Josué 20
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Joṣua pé,
1 O SENHOR também falou a Josué, dizendo:
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kí wọn yan àwọn ìlú ààbò, gẹ́gẹ́ bí mo ti pàṣẹ fún ọ láti ẹnu Mose,
2 Fala aos filhos de Israel, dizendo: Designai para vós cidades de refúgio, das quais eu vos falei pela mão de Moisés;
3 kí ẹni tí ó bá ṣèèṣì pa ènìyàn tàbí tí ó bá pa ènìyàn láìmọ̀-ọ́n-mọ̀ lè sálọ sí ibẹ̀, fún ààbò lọ́wọ́ olùgbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ ẹni tí ó pa.
3 para que fuja para lá o homicida que matar qualquer pessoa por descuido, e involuntariamente; e elas serão o vosso refúgio do vingador do sangue.
4 Nígbà tí ó bá sálọ sí ọ̀kan nínú àwọn ìlú wọ̀nyí, yóò sì dúró ní ẹnu-ọ̀nà àtiwọ ibodè ìlú, kí ó sì ṣe àlàyé ara rẹ̀ ní iwájú àwọn àgbàgbà ìlú náà. Nígbà náà ni wọn yóò gbà á sí ìlú wọn, wọn yóò sì fun ní ibùgbé láàrín wọn.
4 E quando aquele que fugir para uma daquelas cidades estiver de pé à entrada da porta da cidade, e declarar a sua causa aos ouvidos dos anciãos daquela cidade, eles o recebam na cidade e lhe deem um lugar, para que ele possa habitar no meio deles.
5 Bí olùgbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ bá ń lépa rẹ̀, wọn kò gbọdọ̀ fi àwọn ọ̀daràn náà lé wọn lọ́wọ́, nítorí tí ó pa aládùúgbò rẹ̀ láìmọ̀, tí kò sì kórìíra rẹ̀ tẹ́lẹ̀ rí.
5 E se o vingador do sangue o perseguir, eles não entregarão o homicida na sua mão; porquanto feriu o seu próximo involuntariamente, e não o odiou antes.
6 Òun ó sì máa gbé inú ìlú náà, títí yóò fi jẹ́jọ́ níwájú ìjọ ènìyàn àti títí ikú olórí àlùfáà tí ó ń ṣiṣẹ́ ìsìn nígbà náà. Nígbà náà ó lè padà sí ilé rẹ̀ ní ìlú tí ó ti sá wá.”
6 E ele habitará naquela cidade, até que se ponha de pé diante da congregação para julgamento, e até a morte do sumo sacerdote que estiver naqueles dias; então, o homicida retornará, e seguirá para a sua própria cidade, e para a sua própria casa, para a cidade de onde fugiu.
7 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n yan Kedeṣi ní Galili ní ìlú òkè Naftali, Ṣekemu ní ìlú òkè Efraimu, àti Kiriati-Arba (tí í ṣe, Hebroni) ní ìlú òkè Juda.
7 E eles designaram Quedes, na Galileia, no monte Naftali, e Siquém, no monte Efraim, e Quiriate-Arba, que é Hebrom, no monte de Judá.
8 Ní ìhà ìlà-oòrùn Jordani ti Jeriko, wọ́n ya Beseri ní aginjù ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ ní ẹ̀yà Reubeni, Ramoti ní Gileadi ní ẹ̀yà Gadi, àti Golani ní Baṣani ní ẹ̀yà Manase.
8 E, no outro lado do Jordão, nas cercanias de Jericó, em direção ao leste, eles designaram Bezer, no deserto acima da planície da tribo de Rúben, e Ramote, em Gileade, da tribo de Gade, e Golã, em Basã, da tribo de Manassés.
9 Ẹnikẹ́ni nínú àwọn ọmọ Israẹli tàbí àlejò tí ń gbé ní àárín wọn tí ó ṣèèṣì pa ẹnìkan lè sálọ sí àwọn ìlú tí a yà sọ́tọ̀ wọ̀nyí, kí olùgbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ má sì ṣe pa á kí ó to di àkókò tí yóò jẹ́jọ́ níwájú ìjọ ènìyàn.
9 Estas foram as cidades designadas a todos os filhos de Israel, e para o estrangeiro que peregrinar no seu meio, a fim de que todo o que matar qualquer pessoa por descuido possa para lá fugir, e não morrer pela mão do vingador do sangue, até que esteja de pé diante da congregação.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Josué 20, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.