Jeremias 45

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Jeremiah wòlíì sọ fún Baruku ọmọ Neriah ní ọdún kẹrin ti Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda. Lẹ́yìn tí Baruku ti kọ sínú ìwé kíká àwọn ọ̀rọ̀ tí Jeremiah ti ń sọ:
1 A palavra que Jeremias, o profeta, falou para Baruque, o filho de Nerias, quando ele escreveu estas palavras em um livro, da boca de Jeremias, no quarto ano de Jeoiaquim, o filho de Josias, rei de Judá, dizendo:
2 “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ fún ọ, Baruku.
2 Assim diz o SENHOR, o Deus de Israel, para ti, ó Baruque:
3 Ìwọ wí pé, ‘Ègbé ni fún mi! Olúwa ti fi ìbànújẹ́ kún ìrora mi, àárẹ̀ mú mi nínú ẹ̀dùn mi, èmi kò sì rí ìsinmi.’ ”
3 Tu disseste: Ai de mim agora! Porque o SENHOR tem somado tristeza à minha dor. Eu desfaleci em meu lamento, e eu não encontro descanso.
4 Olúwa wí pé sọ èyí fún un, “Èyí ni Ọlọ́run sọ: ‘Èyí tí èmi ti kọ́ ni èmi yóò wò lulẹ̀, àti èyí tí èmi ti gbìn ni èmi yóò fàtu, àní ní orí gbogbo ilẹ̀.
4 Desta forma tu lhe dirás: O SENHOR diz assim: Eis que aquilo que eu construí, eu irei destruir, e aquilo que plantei, irei desarraigar, até mesmo toda esta terra.
5 Ṣé ìwọ sì ń wá ohun títóbi fún ara rẹ? Nítorí náà, má ṣe wá wọn. Èmi yóò mú ibi wá sí orí àwọn ènìyàn gbogbo ni Olúwa wí, ṣùgbọ́n níbikíbi tí ìwọ bá lọ ni èmi yóò jẹ́ kí o sá àsálà pẹ̀lú ẹ̀mí rẹ.’ ”
5 E tu buscas grandes coisas para ti? Não as busques, pois eis que eu trarei o mal sobre toda carne, diz o SENHOR, porém tua vida eu darei a ti por um despojo, em todos os lugares para onde tu fores.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jeremias 45, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.