Jeremias 40
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ọ̀rọ̀ náà sì tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa lẹ́yìn tí Nebusaradani balógun àwọn ẹ̀ṣọ́ ti tú u sílẹ̀ ní Rama. Ó rí Jeremiah tí a fi ẹ̀wọ̀n dè láàrín gbogbo àwọn tí wọ́n mú ní Jerusalẹmu àti Juda. Wọ́n kó lọ sí ilẹ̀ àjèjì Babeli.
1 A palavra que veio a Jeremias da parte do SENHOR, depois que Nebuzaradã, o capitão da guarda, o deixou ir de Ramá, quando o tomou, estando atado em cadeias no meio de todos os que foram levados cativos de Jerusalém e Judá, que foram levados cativos para Babilônia.
2 Nígbà tí balógun ẹ̀ṣọ́ rí Jeremiah, ó sọ fún un wí pé, “Olúwa Ọlọ́run rẹ ni ó pàṣẹ ibí yìí fún mi.
2 E o capitão da guarda tomou Jeremias, e lhe disse: O SENHOR teu Deus proferiu este mal sobre este lugar.
3 Nísinsin yìí, Olúwa ti mú un jáde; ó ti ṣe gẹ́gẹ́ bí ó ti sọ pé òun yóò ṣe. Gbogbo èyí ṣẹlẹ̀ nítorí wí pé ẹ̀yin ènìyàn ṣẹ̀ sí Olúwa, àti pé ẹ kò gbọ́rọ̀ sí àṣẹ rẹ̀.
3 Agora, o SENHOR o trouxe, e fez como havia dito, porque vós pecastes contra o SENHOR, e não obedeceste à sua voz, portanto isto vos sobreveio.
4 Ṣùgbọ́n, ní òní yìí mò ń tú ọ sílẹ̀ kúrò nínú ẹ̀wọ̀n tí ó wà ní ọwọ́ rẹ. Bí o bá fẹ́, tẹ̀lé mi ká lọ sí Babeli, èmi yóò sì bojútó ọ; ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá fẹ́, dúró síbí. Wò ó, gbogbo orílẹ̀-èdè wà níwájú rẹ, lọ sí ibikíbi tí ó bá tẹ́ ọ lọ́rùn.”
4 E agora, eis que te soltei neste dia das correntes que estavam sobre tua mão. Se isto parecer bom para ti vir comigo para Babilônia, venha, e eu irei buscar o teu bem. Porém, se isto parecer mau para ti vir comigo para Babilônia, não venha. Eis que toda a terra está diante de ti. Para onde parecer bom e adequado para ti, para ali vai.
5 Ẹ̀wẹ̀, kí ó tó di pé Jeremiah pẹ̀yìndà láti máa lọ, Nebusaradani fi kún un wí pé, “Padà tọ Gedaliah ọmọ Ahikamu lọ, ọmọ Ṣafani, ẹni tí ọba Babeli ti fi jẹ baálẹ̀ lórí ìlú Juda, kí o sì máa gbé ní àárín àwọn ènìyàn wọ̀nyí tàbí kí o máa lọ ibikíbi tí ó bá tọ́ ní ojú rẹ.”
5 Ora, como ele não tinha voltado ainda, disse: Volta também para Gedalias, o filho de Aicão, o filho de Safã, a quem o rei de Babilônia constituiu governador sobre as cidades de Judá, e habita com ele no meio do povo, ou vai para onde quer que seja adequado para ti. Então o capitão da guarda lhe deu mantimentos, e uma recompensa, e o deixou ir.
6 Báyìí ni Jeremiah lọ sí ọ̀dọ̀ Gedaliah ọmọkùnrin Ahikamu ní Mispa, ó sì dúró tì í láàrín àwọn ènìyàn tí ó ṣẹ́kù ní ilẹ̀ náà.
6 Então, veio Jeremias até Gedalias, o filho de Aicão, para Mispá, e habitou com ele no meio do povo, que foram deixados na terra.
7 Nígbà tí gbogbo àwọn olórí ogun àti àwọn ènìyàn tí wọ́n kù lórí orílẹ̀-èdè náà gbọ́ pé ọba Babeli ti yan Gedaliah ọmọkùnrin Ahikamu gẹ́gẹ́ bí baálẹ̀ ní ilẹ̀ náà; àti pé ó ti fi àwọn ọkùnrin, obìnrin àti ọmọdé tí wọ́n jẹ́ tálákà ní ilẹ̀ náà tí wọn kò kó lọ sí ilẹ̀ àjèjì sí ìkáwọ́ rẹ̀,
7 Ora, quando todos os capitães das forças que estavam nos campos, eles e seus homens, ouviram que o rei de Babilônia tinha feito Gedalias, o filho de Aicão, governador na terra, e o tinha incumbido dos homens, e mulheres, e crianças, e dos pobres da terra, e daqueles que não foram levados cativos para Babilônia;
8 wọ́n wá sí ọ̀dọ̀ Gedaliah ní Mispa; Iṣmaeli ọmọkùnrin Netaniah, Johanani àti Jonatani ọmọkùnrin ti Karea, Seraiah ọmọkùnrin Tanhumeti tí í ṣe ọmọkùnrin Efai ará Netofa àti Jesaniah ọmọkùnrin Maakati àti àwọn ènìyàn wọn.
8 então eles vieram ter com Gedalias a Mispá, Ismael, o filho de Netanias, e Joanã e Jônatas, os filhos de Careá, e Seraías, o filho de Tanumete, e os filhos de Efai, o Netofatita, e Jezanias, o filho de um maacatita, eles e seus homens.
9 Gedaliah ọmọkùnrin Ahikamu, ọmọkùnrin ti Ṣafani ṣe ìbúra láti tún fi dá àwọn ènìyàn lójú pé, “Ẹ má ṣe bẹ̀rù láti sin àwọn Babeli.” Ó sọ wí pé, “Gbé ilẹ̀ náà kí ẹ sì máa sin ọba Babeli, yóò sì dára fún un yín.
9 E Gedalias, o filho de Aicão, o filho de Safã, jurou a eles e aos seus homens, dizendo: Não temais servir aos caldeus; habitai na terra, e servi o rei de Babilônia, e isto vos irá bem.
10 Èmi fúnra mi yóò dúró ní Mispa láti ṣojú yín níwájú Babeli tí wọ́n tọ̀ wá wá. Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ni yóò máa kórè ọtí wáìnì, èso igi àti òróró; kí ẹ sì kó wọn sí inú àpò àpamọ́wọ́ yín; kí ẹ̀yin sì máa gbé ní ìlú tí ẹ ti gbà.”
10 Com relação a mim, eis que eu habitarei em Mispá, para servir aos caldeus, que virão até nós. Porém vós, ajuntai vinho, e frutos de verão, e azeite, e colocai-os em vossos vasos, e habitai em vossas cidades, que tomaste.
11 Nígbà tí gbogbo àwọn Juda ní Moabu, Ammoni, Edomu àti gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè gbọ́ pé ọba Babeli ti fi ohun tókù sílẹ̀ ní Juda, àti pé ó ti yan Gedaliah ọmọkùnrin Ahikamu ọmọkùnrin Ṣafani gẹ́gẹ́ bí gómìnà lórí wọn.
11 Da mesma forma quando todos os judeus que estavam em Moabe, e no meio dos amonitas, e em Edom, e que estavam em todas as regiões, ouviram que o rei de Babilônia tinha deixado um remanescente de Judá, e que ele tinha colocado sobre eles Gedalias, o filho de Aicão, o filho de Safã;
12 Gbogbo wọn padà wá sí ilẹ̀ Juda sọ́dọ̀ Gedaliah ní Mispa láti orílẹ̀-èdè gbogbo tí a ti lé wọn sí. Wọ́n sì kórè ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọtí wáìnì àti èso igi.
12 retornaram todos os judeus de todos os lugares para onde eles foram lançados, e vieram para a terra de Judá, para Gedalias, até Mispá, e ajuntaram vinho e frutos de verão com muita abundância.
13 Johanani ọmọkùnrin ti Karea àti gbogbo àwọn olórí ogun tí ó kù ní orílẹ̀-èdè sì tọ Gedaliah wá ní Mispa.
13 Além disso, Joanã, o filho de Careá, e todos os capitães das forças que estavam nos campos, vieram a Gedalias, para Mispá.
14 Wọ́n sì sọ fún un wí pé, “Ǹjẹ́ ìwọ ha mọ̀ pé Baalisi ọba àwọn Ammoni ti rán Iṣmaeli ọmọkùnrin Netaniah láti lọ mú ẹ̀mí rẹ?” Ṣùgbọ́n Gedaliah ọmọkùnrin ti Ahikamu kò gbà wọ́n gbọ́.
14 E lhe disseram: Tu sabes certamente que Baalis, o rei dos amonitas, enviou Ismael, o filho de Netanias, para te matar? Porém Gedalias, o filho de Aicão, não acreditou neles.
15 Nígbà náà ni Johanani ọmọkùnrin Karea sọ ní ìkọ̀kọ̀ fún Gedaliah ní Mispa pé, “Jẹ́ kí èmi lọ pa Iṣmaeli ọmọkùnrin Netaniah, ẹnikẹ́ni kò sì ní mọ èyí. Kí ni ìdí rẹ̀ tí yóò ṣe mú ẹ̀mí rẹ, tí o sì ṣe fẹ́ mú àwọn Júù tí ó yí ọ ká túká, kí ìyókù Juda sì parun?”
15 Então Joanã, o filho de Careá, falou a Gedalias em Mispá secretamente, dizendo: Permita-me ir, rogo-te, e eu irei matar Ismael, o filho de Netanias, e nenhum homem o saberá. Por que razão deveria ele matar-te, para que todos os judeus que estão reunidos a ti sejam espalhados e o remanescente de Judá pereça?
16 Ṣùgbọ́n Gedaliah ọmọ Ahikamu sọ fún Johanani ọmọ Karea pé, “Má ṣe ṣe nǹkan yìí! Nítorí nǹkan tí ò ń sọ nípa Iṣmaeli kì í ṣe òtítọ́.”
16 Porém Gedalias, o filho de Aicão, disse a Joanã, o filho de Careá: Tu não farás isto, pois tu falas falsamente de Ismael.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jeremias 40, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.