Jeremias 39
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ó sì ṣe, nígbà tí a kó Jerusalẹmu, ní ọdún kẹsànán Sedekiah, ọba Juda, nínú oṣù kẹwàá, Nebukadnessari ọba Babeli gbógun ti Jerusalẹmu pẹ̀lú gbogbo ogun rẹ̀, wọ́n sì dó tì í.
1 No nono ano de Zedequias, rei de Judá, no décimo mês, veio Nabucodonosor, rei de Babilônia e todo o seu exército contra Jerusalém, e a sitiaram.
2 Ní ọjọ́ kẹsànán, oṣù kẹrin ọdún kọkànlá Sedekiah, ni a wó odi ìlú náà.
2 E no décimo primeiro ano de Zedequias, no quarto mês, o nono dia do mês, a cidade foi desmantelada.
3 Nígbà náà ni gbogbo àwọn ìjòyè ọba Babeli wá, wọ́n sì jókòó ní àárín ẹnu ibodè, àní Nergali-Ṣareseri ti Samgari, Nebo-Sarsikimu olórí ìwẹ̀fà, Nergali-Ṣareseri, olórí amòye, pẹ̀lú gbogbo àwọn ìjòyè ọba Babeli yóò kú.
3 E todos os príncipes do rei de Babilônia entraram, e assentaram-se na porta do meio: Nergal-Sarezer, Sangar-Nebo, Sarsequim, Rabe-Saris, Nergal-Sarezer, Rabe-Mague, e todo o restante dos príncipes do rei de Babilônia.
4 Nígbà tí Sedekiah ọba Juda àti àwọn ọmọ-ogun rí wọn, wọ́n sá, wọ́n kúrò ní ìlú ní alẹ́, wọ́n gba ọ̀nà ọgbà ọba lọ láàrín ẹnu ibodè pẹ̀lú odi méjì, wọ́n dojúkọ aginjù.
4 E aconteceu que, quando Zedequias, o rei de Judá os viu, e todos os homens de guerra, então eles fugiram, e saíram da cidade à noite, pelo caminho do jardim do rei, pelo portão entre os dois muros. E ele partiu pelo caminho da planície.
5 Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ọmọ-ogun Babeli lé wọn, wọ́n bá Sedekiah láàrín aginjù Jeriko. Wọ́n mú un ní ìgbèkùn, wọ́n sì mú u tọ Nebukadnessari ọba Babeli àti Ribla ní ilẹ̀ Hamati, níbi tí wọ́n ti ṣe ìdájọ́ rẹ̀.
5 Porém, o exército dos caldeus os perseguiu e alcançaram Zedequias nas planícies de Jericó. E quando eles o tinham capturado, eles o trouxeram até Nabucodonosor, rei de Babilônia, até Ribla na terra de Hamate, onde o sentenciou.
6 Níbẹ̀ ní Ribla, ni ọba Babeli ti dúńbú àwọn ọmọ Sedekiah lójú rẹ̀, tí ó sì tún pa gbogbo àwọn ọlọ́lá ilẹ̀ Juda.
6 Então o rei de Babilônia matou os filhos de Zedequias em Ribla perante os seus olhos. Também o rei de Babilônia matou todos os nobres de Judá.
7 Nígbà náà ni ó fọ́ ojú Sedekiah, ó sì dè é pẹ̀lú ẹ̀wọ̀n láti gbé e lọ sí ilẹ̀ Babeli.
7 E também arrancou os olhos de Zedequias, e o amarrou com correntes, para o transportar para a Babilônia.
8 Àwọn Babeli dáná sun ààfin ọba àti ilé àwọn ènìyàn, wọ́n sì wó odi Jerusalẹmu.
8 E os caldeus queimaram a casa do rei e as casas do povo a fogo, e demoliram os muros de Jerusalém.
9 Nebusaradani olórí àwọn ọmọ-ogun mú lọ sí ìgbèkùn Babeli pẹ̀lú gbogbo àwọn tí ó ṣẹ́kù nínú ìlú.
9 Então, Nebuzaradã, o capitão da guarda, levou cativo para a Babilônia o remanescente do povo que ficou na cidade, e os desertores que passaram para ele, com o restante do povo que permaneceu.
10 Ṣùgbọ́n Nebusaradani olórí ogun fi àwọn aláìní sílẹ̀ ní Juda, àwọn tí kò ní ohun kankan ní àkókò náà, ó fún wọn ní ọgbà àjàrà àti oko.
10 Porém, Nebuzaradã, o capitão da guarda, deixou os pobres do povo, que nada tinham na terra de Judá, e deu-lhes vinhas e campos ao mesmo tempo.
11 Nísinsin yìí, Nebukadnessari ọba àwọn Babeli pàṣẹ lórí Jeremiah, láti ọ̀dọ̀ Nebusaradani olórí ogun wá wí pé:
11 Ora, Nabucodonosor, rei de Babilônia, deu ordem a respeito de Jeremias a Nebuzaradã, o capitão da guarda, dizendo:
12 “Ẹ gbé e, kí ẹ sì bojútó o. Ẹ má ṣe ṣe ohun búburú fún un, ṣùgbọ́n ohunkóhun tó bá béèrè ni kí ẹ fi fún un.”
12 Toma-o, e busque bem-estar para ele e não lhe faças mal, porém faz para com ele exatamente como ele te dirá.
13 Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ pẹ̀lú, Nebusaradani balógun ìṣọ́, àti Nebusaradani olórí ìwẹ̀fà, àti Nergali-Ṣareseri, olórí amòye àti gbogbo àwọn ìjòyè ọba Babeli,
13 Então enviou Nebuzaradã, o capitão da guarda, e Nebusazbã, Rabe-Saris, e Nergal-Sarezer, o Rabe-Mague, e todos os príncipes do rei de Babilônia.
14 ránṣẹ́ láti mú Jeremiah kúrò nínú túbú. Wọ́n gbé e lọ fún Gedaliah ọmọ Ahikamu ọmọ Ṣafani láti mú padà lọ sí ilé àti máa wà pẹ̀lú àwọn ènìyàn rẹ̀.
14 Eles enviaram, e retiraram Jeremias do átrio da prisão, e incumbiram a Gedalias, o filho de Aicão, o filho de Safã, para que ele o levasse para casa. Então ele habitou entre o povo.
15 Nígbà tí Jeremiah wà nínú túbú, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ ọ́ wá wí pé:
15 Ora, a palavra do SENHOR veio até Jeremias, enquanto ele estava trancado no átrio da prisão, dizendo:
16 “Lọ sọ fún Ebedimeleki ará Kuṣi, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí: Èmi ṣetán láti mú ọ̀rọ̀ mi ṣẹ lórí ìlú yìí nípa àjálù kì í ṣe àlàáfíà. Ní àkókò náà ni yóò ṣẹ lójú rẹ.
16 Vai e fala a Ebede-Meleque, o etíope, dizendo: Assim diz o SENHOR dos Exércitos, o Deus de Israel: Eis que eu trarei minhas palavras sobre esta cidade para o mal, e não para o bem, e elas se cumprirão naquele dia diante de ti.
17 Ṣùgbọ́n, Èmi yóò gbà ọ́ lọ́jọ́ náà ni Olúwa wí. A kò ní fi ọ́ lé ọwọ́ àwọn tí o bẹ̀rù.
17 Porém, eu livrarei a ti naquele dia, diz o SENHOR, e tu não serás dado na mão dos homens aos quais temes.
18 Èmi yóò gbà ọ́ là; o kò ní ṣubú láti ipa idà; ṣùgbọ́n ìwọ yóò sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ, nítorí pé ìwọ ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú mi, ni Olúwa wí.’ ”
18 Porque eu certamente te livrarei, e tu não cairás pela espada, porém a tua vida será por um despojo para ti, porque tu tens colocado tua confiança em mim, diz o SENHOR.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jeremias 39, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.