Jeremias 38
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ṣefatia ọmọ Mattani, Gedaliah ọmọ Paṣuri, Jehukali ọmọ Ṣelemiah, àti Paṣuri ọmọ Malkiah, gbọ́ ohun tí Jeremiah ń sọ fún àwọn ènìyàn nígbà tí ó sọ wí pé,
1 Então Sefatias, o filho de Matã, e Gedalias, o filho de Pasur, e Jucal, o filho de Selemias, e Pasur, o filho de Malquias, ouviram as palavras que Jeremias anunciou a todo o povo, dizendo:
2 “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Ẹnikẹ́ni tó bá dúró nínú ìlú yìí yóò kú nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn; ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tó bá lọ sí Babeli yóò yè; yóò sá àsálà, yóò sì yè.’
2 Assim diz o SENHOR: Aquele que permanecer nesta cidade morrerá pela espada, pela fome, e pela peste. Porém aquele que for para os caldeus viverá, pois ele terá sua vida por despojo, e viverá.
3 Àti pé èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Ìdánilójú wà wí pé a ó fi ìlú náà lé ọwọ́ àwọn ọmọ-ogun ọba Babeli; tí yóò sì kó wa nígbèkùn.’ ”
3 Assim diz o SENHOR: Esta cidade certamente será dada na mão do exército do rei de Babilônia, que a tomará.
4 Nígbà náà ni àwọn ìjòyè wí fún ọba pé, “Ó yẹ kí a pa ọkùnrin yìí; ó ń kó ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn ọmọ-ogun tókù nínú ìlú pẹ̀lú gbogbo àwọn ènìyàn nípa ohun tí ó ń sọ fún wọn. Ọkùnrin yìí kò fẹ́ ìre fún àwọn ènìyàn bí kò ṣe ìparun.”
4 Portanto, os príncipes disseram ao rei: Nós te suplicamos que este homem seja executado, porque ele enfraquece as mãos dos homens de guerra que restam nesta cidade, e as mãos de todo o povo, ao lhes falar tais palavras, pois este homem não busca o bem deste povo, porém o mal.
5 Sedekiah ọba sì wí pé, “Ó wà lọ́wọ́ yín. Ọba kò lè ṣe ohunkóhun láti takò yín.”
5 Então, Zedequias, o rei, disse: Eis que ele está em vossa mão, pois não é o rei quem possa fazer coisa alguma contra vós.
6 Wọ́n gbé Jeremiah sọ sínú ihò Malkiah, ọmọ ọba, tí ó wà ní àgbàlá ilé túbú; wọ́n fi okùn sọ Jeremiah kalẹ̀ sí ìsàlẹ̀ ihò; kò sì ṣí omi nínú ihò náà bí kò ṣe ẹrọ̀fọ̀, Jeremiah sì rì sínú ẹrọ̀fọ̀ náà.
6 Então tomaram eles a Jeremias, e o lançaram na masmorra de Malquias, o filho de Hameleque, que estava no átrio da prisão, e eles desceram Jeremias com cordas. E na masmorra não havia água, porém lama, então Jeremias atolou-se na lama.
7 Ṣùgbọ́n, Ebedimeleki, ará Kuṣi ìjòyè nínú ààfin ọba gbọ́ pé wọ́n ti ju Jeremiah sínú kànga. Nígbà tí ọba jókòó ní ẹnu-bodè Benjamini.
7 Ora, quando Ebede-Meleque, o etíope, um dos eunucos que estava na casa do rei, soube que eles tinham colocado Jeremias na masmorra; porém o rei estava assentando ao portão de Benjamim.
8 Ebedimeleki jáde kúrò láàfin ọba, ó sì sọ fún un pé,
8 Ebede-Meleque saiu da casa do rei, e falou ao rei, dizendo:
9 “Olúwa mi ọba, àwọn ènìyàn wọ̀nyí ti ṣe ohun búburú sí Jeremiah wòlíì Ọlọ́run. Wọ́n ti gbé e sọ sínú kànga níbi tí kò sí oúnjẹ kankan nínú ìlú mọ́.”
9 Meu senhor, ó rei, estes homens fizeram o mal em tudo o que eles têm feito a Jeremias, o profeta, a quem lançaram na masmorra, e ele está a morrer pela fome no lugar onde se acha, pois não há mais pão na cidade.
10 Nígbà náà ni ọba pàṣẹ fún Ebedimeleki ará Kuṣi pé, “Mú ọgbọ̀n ọkùnrin láti ibí pẹ̀lú rẹ, kí ẹ sì fa wòlíì Jeremiah sókè láti inú ihò, kí ó tó kú.”
10 Então, o rei ordenou a Ebede-Meleque, o etíope, dizendo: Toma daqui trinta homens contigo, e tira Jeremias, o profeta, para fora da masmorra, antes que ele morra.
11 Ebedimeleki kó àwọn ọkùnrin náà pẹ̀lú rẹ̀, wọ́n lọ sínú yàrá kan nínú ààfin ọba. Ó mú àwọn aṣọ àkísà àti okùn tọ Jeremiah lọ nínú kànga.
11 Então Ebede-Meleque tomou os homens com ele, e adentrou a casa do rei, sob a tesouraria, e tomou dali pedaços de panos velhos torcidos e trapos puídos velhos, e deixou-os descer por cordas para dentro da masmorra, até Jeremias.
12 Ebedimeleki ará Kuṣi sọ fún Jeremiah pé, “Fi àkísà àti okùn bọ abẹ́ abíyá rẹ, Jeremiah sì ṣe bẹ́ẹ̀.”
12 E, Ebede-Meleque, o etíope disse para Jeremias: Coloca agora estes velhos pedaços de tecido torcidos e trapos puídos sob tuas axilas, por debaixo das cordas. E Jeremias o fez.
13 Báyìí ni wọ́n ṣe fi okùn yọ Jeremiah jáde, wọ́n sì mu un gòkè láti inú ihò wá, Jeremiah sì wà ní àgbàlá ilé túbú.
13 Então eles alçaram Jeremias com as cordas, e o ergueram para fora da masmorra, e Jeremias permaneceu no átrio da prisão.
14 Nígbà náà ni ọba Sedekiah ránṣẹ́ pe, Jeremiah òjíṣẹ́ Ọlọ́run àti láti mú un wá sí ẹnu ibodè kẹta nílé Olúwa. Ọba sì sọ fún Jeremiah pé, “Èmi yóò bi ọ́ ní ohun kan; má sì ṣe fi ohun kan pamọ́ fún mi.”
14 Então, enviou o rei Zedequias, e trouxe Jeremias, o profeta, até ele, à terceira entrada que está na casa do SENHOR. E o rei disse a Jeremias: Eu perguntarei a ti uma coisa, nada escondas de mim.
15 Jeremiah sì sọ fún Sedekiah pé, “Tí mo bá fún ọ ní èsì, ṣé o kò nípa mí? Tí mo bá gbà ọ́ nímọ̀ràn, o kò ní gbọ́ tèmi.”
15 Então Jeremias disse a Zedequias: Se eu o declarar para ti, certamente não irás tu me matar? E se eu der a ti conselho, não me escutarás.
16 Ṣùgbọ́n ọba Sedekiah búra ní ìkọ̀kọ̀ fún Jeremiah wí pé, “Dájúdájú bí Olúwa ti ń bẹ, ẹni tí ó fún wa ní ẹ̀mí, èmi kò nípa ọ́ tàbí fà ọ́ fún àwọn tó ń lépa ẹ̀mí rẹ.”
16 Então, Zedequias, o rei, jurou secretamente para Jeremias, dizendo: Como o SENHOR vive, que nos fez esta alma, eu não te matarei, nem te darei na mão destes homens que buscam a tua vida.
17 Nígbà náà ni Jeremiah sọ fún Sedekiah pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run alágbára, Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Àyàfi bí o bá jọ̀wọ́ ara rẹ fún àwọn olóyè ọba Babeli, a ó dá ẹ̀mí rẹ sí àti pé ìlú yìí kò ní di jíjó ní iná; ìwọ àti ilé rẹ yóò sì wà láààyè.
17 Então disse Jeremias para Zedequias: Assim diz o SENHOR, o Deus dos Exércitos, o Deus de Israel: Se tu saíres até os príncipes do rei de Babilônia, então tua alma viverá, e esta cidade não será queimada a fogo, e tu viverás, e a tua casa.
18 Ṣùgbọ́n tí o kò bá jọ̀wọ́ ara rẹ fún àwọn ìjòyè ọba Babeli, a ó fa ìlú yìí lé ọwọ́ àwọn Babeli. Wọn yóò sì fi iná sun ún, ìwọ gan an kò ní le sá mọ́ wọn lọ́wọ́.’ ”
18 Porém, se tu não saíres aos príncipes do rei de Babilônia, então esta cidade será dada na mão dos caldeus, e eles a queimarão a fogo, e tu não escaparás das suas mãos.
19 Ọba Sedekiah sọ fún Jeremiah pé, “Mò ń bẹ̀rù àwọn Júù tó ti sálọ sí ilẹ̀ Babeli, nítorí pé àwọn ará Babeli lè fà mí lé wọn lọ́wọ́ láti fìyà jẹ mí.”
19 E, Zedequias, o rei, disse para Jeremias: Eu estou temeroso dos judeus que estão com os caldeus, que me entreguem nas mãos deles, e eles zombem de mim.
20 Jeremiah sì dáhùn wí pé, “Wọn kò ní fi ọ́ lé e lọ́wọ́. Pa ọ̀rọ̀ Olúwa mọ́ nípa ṣíṣe ohun tí mo sọ fún ọ; yóò sì dára fún ọ, ẹ̀mí rẹ yóò sì wà.
20 Mas Jeremias disse: Eles não te entregarão. Ouve, rogo-te, a voz do SENHOR, conforme te falo, e isto será bem para ti, e tua alma viverá.
21 Ṣùgbọ́n bí ìwọ bá kọ̀ láti jọ̀wọ́ ara rẹ, èyí ni ohun tí Olúwa ti fihàn mí.
21 Porém se tu te recusares a sair, esta é a palavra que me mostrou o SENHOR.
22 Gbogbo àwọn obìnrin tókù ní ààfin ọba Juda ni wọn yóò kó jáde fún àwọn ìjòyè ọba Babeli. Àwọn obìnrin náà yóò sì sọ fún ọ pé:
22 E eis que, todas as mulheres que ficarem na casa do rei de Judá, serão levadas para os príncipes do rei de Babilônia, e aquelas mulheres dirão: Teus amigos te incitaram e prevaleceram contra ti; teus pés estão afundados na lama, e retrocederam.
23 “Wọn yóò kó àwọn ìyàwó àti ọmọ rẹ wá sí Babeli. Ìwọ gan an kò ní bọ́ níbẹ̀, ọba Babeli yóò mú ọ, wọn yóò sì jó ìlú yìí kanlẹ̀.”
23 Então eles darão todas as tuas esposas e teus filhos para os caldeus, e tu não escaparás da sua mão, porém tu serás capturado pela mão do rei de Babilônia, e tu farás esta cidade ser queimada a fogo.
24 Nígbà náà ni Sedekiah sọ fún Jeremiah pé, “Má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni mọ̀ nípa ọ̀rọ̀ yìí, tàbí kí o kú.
24 Então disse Zedequias para Jeremias: Nenhum homem saiba estas palavras, e tu não morrerás.
25 Tí àwọn ìjòyè bá mọ̀ pé mo bá ọ sọ̀rọ̀, tí wọ́n bá wá bá ọ wí pé, ‘Sọ fún wa ohun tí o bá ọba sọ tàbí ohun tí ọba sọ fún ọ; má ṣe fi pamọ́ fún wa tàbí kí a pa ọ́,’
25 Porém, se os príncipes ouvirem que eu falei contigo, e vierem a ti, e disserem para ti: Declara para nós agora aquilo que disseste ao rei, e o que ele te disse, não nos escondas nada, e não te mataremos.
26 nígbà náà kí o sọ fún wọn, ‘Mò ń bẹ ọba láti má jẹ́ kí n padà lọ sí ilé Jonatani láti lọ kú síbẹ̀.’ ”
26 Então tu lhes dirás: Eu apresentei minha súplica perante o rei, para que ele não me fizesse retornar à casa de Jônatas, para ali morrer.
27 Gbogbo àwọn olóyè sì wá sí ọ̀dọ̀ Jeremiah láti bi í léèrè, ó sì sọ gbogbo ohun tí ọba ní kí ó sọ. Wọn kò sì sọ ohunkóhun mọ́, nítorí kò sí ẹni tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ tí òun àti ọba jọ sọ.
27 Então, vieram todos os príncipes até Jeremias, e lhe perguntaram; e ele contou-lhes, conforme todas estas palavras que o rei ordenou. Então, eles deixaram de falar com ele, pois a questão não fora revelada.
28 Jeremiah wà nínú àgbàlá àwọn ẹ̀ṣọ́ títí di ọjọ́ tí wọ́n fi kó Jerusalẹmu:
28 Então, Jeremias morou no átrio da prisão até o dia em que Jerusalém foi tomada, e ele estava lá quando Jerusalém foi tomada.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jeremias 38, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.