Jeremias 28

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Ní oṣù karùn-ún ní ọdún kan náà, ọdún kẹrin ní ìbẹ̀rẹ̀ ìṣèjọba Sedekiah ọba Juda, wòlíì Hananiah ọmọ Assuri, tí ó wá láti Gibeoni, sọ fún mi ní ilé Olúwa tí ó wà ní iwájú àwọn àlùfáà àti gbogbo ènìyàn:
1 E isto aconteceu no mesmo ano, no início do reinado de Zedequias, rei de Judá, no quarto ano, e no quinto mês, que Hananias, o filho de Azur, o profeta que era de Gibeão, me falou na casa do SENHOR, na presença dos sacerdotes, e de todo o povo, dizendo:
2 “Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Èmi yóò mú àjàgà ọba Babeli rọrùn.
2 Assim fala o SENHOR dos Exércitos, o Deus de Israel, dizendo: Eu quebrei o jugo do rei de Babilônia.
3 Láàrín ọdún méjì, Èmi yóò mú gbogbo ohun èlò tí ọba Nebukadnessari; ọba Babeli kó kúrò ní ilé Olúwa tí ó sì kó lọ sí Babeli padà wá.
3 Dentro de dois anos, trarei novamente para este lugar todos os vasos da casa do SENHOR, que Nabucodonosor, rei de Babilônia, tomou deste lugar, carregando-os para Babilônia.
4 Èmi á tún mú ààyè Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda padà, àti gbogbo àwọn tí ń ṣe àtìpó láti Juda ní Babeli,’ èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa pé, ‘àjàgà yín láti ọwọ́ ọba Babeli yóò rọrùn.’ ”
4 E eu trarei novamente para este lugar Jeconias, o filho de Jeoiaquim, rei de Judá, com todos os cativos de Judá, que entraram em Babilônia, diz o SENHOR, pois eu quebrarei o jugo do rei de Babilônia.
5 Wòlíì Jeremiah wí fún wòlíì Hananiah ní iwájú ọmọ àlùfáà àti àwọn ènìyàn tí wọ́n dúró ní ilé Olúwa.
5 Então o profeta Jeremias disse para o profeta Hananias, na presença dos sacerdotes, e na presença de todo o povo que estava na casa do SENHOR.
6 Jeremiah wòlíì wí pé, “Àmín! Kí Olúwa kí ó ṣe bẹ́ẹ̀! Kí Olúwa kí ó mú ọ̀rọ̀ rẹ̀ tí ìwọ sọ àsọtẹ́lẹ̀ ṣẹ, láti mú ohun èlò ilé Olúwa àti gbogbo àwọn ìgbèkùn láti ilẹ̀ Babeli padà wá sí ibí yìí.
6 Disse pois o profeta Jeremias: Amém, assim faça o SENHOR. O SENHOR cumpra as tuas palavras que profetizaste, e torne a trazer os vasos da casa do SENHOR, e todos que foram levados cativos, desde Babilônia até este lugar.
7 Nísinsin yìí, ìwọ gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí tí mo sọ sí etí rẹ àti sí etí gbogbo ènìyàn.
7 Porém, ouve agora esta palavra, que eu falo aos teus ouvidos, e aos ouvidos de todo o povo.
8 Ní ìbẹ̀rẹ̀ àwọn wòlíì tí ó ṣáájú rẹ àti èmi ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ ogun, ibi àti àjàkálẹ̀ sí ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè.
8 Os profetas que existiram antes de mim e antes de ti, desde a antiguidade, profetizaram contra muitas regiões, e contra grandes reinos, sobre guerra, e mal, e peste.
9 Ṣùgbọ́n, àwọn wòlíì tí ó ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ àlàáfíà ni a mọ̀ gẹ́gẹ́ bí wòlíì olóòtítọ́ tí Olúwa rán, tí àsọtẹ́lẹ̀ rẹ bá wá sí ìmúṣẹ.”
9 O profeta que profetizar paz, quando a palavra do profeta se cumprir, então será o profeta conhecido, que o SENHOR verdadeiramente o enviou.
10 Wòlíì Hananiah gbé àjàgà ọrùn wòlíì Jeremiah kúrò, ó sì fọ́ ọ.
10 Então Hananias, o profeta, tirou o jugo do pescoço do profeta Jeremias, e o quebrou.
11 Hananiah sọ níwájú gbogbo ènìyàn wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Bákan náà ni Èmi yóò fọ́ àjàgà ọrùn Nebukadnessari, ọba Babeli láàrín ọdún méjì.’ ” Wòlíì Jeremiah sì bá ọ̀nà tirẹ̀ lọ.
11 E Hananias falou na presença de todo o povo, dizendo: Assim diz o SENHOR: Dentro de dois anos completos, quebrarei o jugo de Nabucodonosor, rei de Babilônia, do pescoço de todas as nações. E o profeta Jeremias tomou o seu caminho.
12 Láìpẹ́ ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wòlíì wá lẹ́yìn ìgbà tí wòlíì Hananiah ti gbé àjàgà kúrò ní ọrùn wòlíì Jeremiah wí pé:
12 Então a palavra do SENHOR veio a Jeremias, o profeta, depois que Hananias, o profeta, quebrou o jugo do pescoço do profeta Jeremias, dizendo:
13 “Lọ sọ fún Hananiah, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí, ìwọ ti wó àjàgà onígi, ṣùgbọ́n ní ààyè wọn, wà á bá àjàgà onírin.
13 Vai e fala a Hananias, dizendo: Assim diz o SENHOR: Tu quebraste os jugos de madeira, mas tu lhes farás jugos de ferro.
14 Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí: Èmi yóò fi àjàgà onírin sí ọrùn gbogbo orílẹ̀-èdè láti lè máa sin Nebukadnessari ọba Babeli, àti pé gbogbo yín ni ẹ̀ ó máa sìn ín. Èmi yóò tún fún un ní àṣẹ lórí àwọn ẹranko búburú.’ ”
14 Porque assim diz o SENHOR dos Exércitos, o Deus de Israel: Eu coloquei um jugo de ferro sobre o pescoço de todas estas nações, para que elas possam servir a Nabucodonosor, rei de Babilônia. E elas o servirão, e eu também lhe dei os animais do campo.
15 Wòlíì Jeremiah sọ fún wòlíì Hananiah pé, “Gbọ́ ọ, Hananiah! Olúwa kò rán ọ, síbẹ̀, ìwọ jẹ́ kí orílẹ̀-èdè yìí gba irọ́ gbọ́.
15 Então disse o profeta Jeremias ao profeta Hananias: Ouve agora, Hananias: O SENHOR não te enviou, porém tu fazes este povo confiar em uma mentira.
16 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Mo ṣetán láti mú ọ kúrò nínú ayé, ní ọdún yìí ni ìwọ yóò kú nítorí o ti wàásù ọ̀tẹ̀ sí Olúwa.’ ”
16 Portanto assim diz o SENHOR: Eis que te expulsarei da face da terra. Este ano tu morrerás, porque ensinaste rebelião contra o SENHOR.
17 Ní oṣù keje ọdún yìí ni Hananiah wòlíì kú.
17 Assim o profeta Hananias morreu no mesmo ano, no sétimo mês.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jeremias 28, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.