Jeremias 24
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Lẹ́yìn tí Nebukadnessari ọba Babeli ti kó Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn oníṣọ̀nà àti oníṣẹ́ ọwọ́ ti Juda lọ sí ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí ilẹ̀ àjèjì Babeli tán. Olúwa fi agbọ̀n èso ọ̀pọ̀tọ́ méjì hàn mí tí a gbé sí iwájú pẹpẹ Olúwa.
1 O SENHOR me mostrou, e, eis que dois cestos de figos foram colocados perante o templo do SENHOR, depois que Nabucodonosor, rei de Babilônia, levou cativo Jeconias, o filho de Jeoiaquim, rei de Judá, e os príncipes de Judá, com os carpinteiros e ferreiros, de Jerusalém, e os levou para Babilônia.
2 Agbọ̀n kan ni èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó dára bí èyí tí ó tètè pọ́n; èkejì sì ní èso ọ̀pọ̀tọ́ tí ó burú rékọjá tí kò sì le è ṣe é jẹ.
2 Um cesto tinha figos muito bons, como os figos que são da primeira maturação, e o outro cesto tinha figos muito ruins, os quais não podiam ser comidos, pois eram muito ruins.
3 Nígbà náà ni Olúwa bi mí pé, “Kí ni ìwọ rí Jeremiah?”
3 Então disse-me o SENHOR: O que vês tu, Jeremias? E eu disse: Figos; os bons figos, muito bons, e os ruins, muito ruins, que não podem ser comidos, pois são muito ruins.
4 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
4 Novamente a palavra do SENHOR veio a mim, dizendo:
5 “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Gẹ́gẹ́ bí àwọn èso ọ̀pọ̀tọ́ dáradára yìí ni Èmi yóò ka àwọn tí wọ́n lọ sí ilẹ̀ àjèjì láti Juda sí tí èmi rán jáde kúrò ní ibí yìí lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Kaldea.
5 Assim diz o SENHOR, o Deus de Israel: Como a estes bons figos, assim eu reconhecerei aqueles que foram levados cativos de Judá, e que eu enviei deste lugar, para a terra dos caldeus, para o seu bem.
6 Ojú mi yóò máa ṣọ́ wọn lọ fún rere, Èmi yóò gbé wọn ró, n kò ní já wọn lulẹ̀. Èmi yóò gbìn wọ́n, n kò sì ní fà wọ́n tu.
6 Porque eu colocarei meus olhos sobre eles para o bem, e eu os trarei novamente para esta terra. E eu os edificarei, e não os destruirei; e eu os plantarei, e não os removerei completamente.
7 Èmi yóò fún wọn ní ọkàn láti mọ̀ mí pé, “Èmi ni Olúwa.” Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi; Èmi ni yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn; nítorí pé wọn yóò padà sọ́dọ̀ mi pẹ̀lú gbogbo ọkàn wọn.
7 E eu lhes darei um coração para que me conheçam, que eu sou o SENHOR. E eles serão o meu povo, e eu serei o seu Deus, porque eles retornarão a mim de todo coração.
8 “ ‘Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí èso ọ̀pọ̀tọ́ tí kò dára, tí ó burú tí kò ṣe é jẹ,’ ni Olúwa wí, ‘bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò ṣe pẹ̀lú Sedekiah ọba Juda, àwọn ìjòyè rẹ̀ àti àwọn tí ó yẹ ní Jerusalẹmu, yálà wọ́n wà lórí ilẹ̀ yìí tàbí wọ́n ń gbé Ejibiti.
8 E como os figos ruins, que não podem ser comidos, pois são muito ruins, certamente assim diz o SENHOR: Deste modo entregarei Zedequias, rei de Judá, e seus príncipes, e o restante de Jerusalém, que restarem nesta terra, e aqueles que habitarem na terra do Egito.
9 Èmi yóò sọ wọ́n di ìwọ̀sí àti ẹni ibi nínú gbogbo ìjọba ayé, láti di ẹni ìfibú àti ẹni òwe, ẹni ẹ̀sín, àti ẹni ẹ̀gàn ní ibi gbogbo tí Èmi ó lé wọn sí.
9 E eu os entregarei para serem removidos para todos os reinos da terra, para que sofram, e sejam uma desonra, e um provérbio, um insulto, e uma maldição em todos os lugares para onde eu os levarei.
10 Èmi yóò rán idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn sí wọn, títí tí gbogbo wọn yóò parun lórí ilẹ̀ tí a fún wọn àti fún àwọn baba wọn.’ ”
10 E eu enviarei entre eles a espada, a fome e a peste, até que sejam consumidos de sobre a terra que eu lhes dei, e a seus pais.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jeremias 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.