Jeremias 21

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jeremiah wá nígbà tí ọba Sedekiah rán Paṣuri ọmọ Malkiah àti àlùfáà Sefaniah ọmọ Maaseiah sí i; wọ́n wí pé:
1 Palavra que veio para Jeremias da parte do SENHOR, quando o rei Zedequias lhe enviou a Pasur, o filho de Malquias, e Sofonias, o filho de Maaseias, o sacerdote, dizendo:
2 “Wádìí lọ́wọ́ Olúwa fún wa nítorí Nebukadnessari ọba Babeli ń kọlù wá. Bóyá Olúwa yóò ṣe ìyanu fún wa gẹ́gẹ́ bí ti àtẹ̀yìnwá, kí ó sì yípadà kúrò lọ́dọ̀ wa.”
2 Indague, eu te rogo, ao SENHOR por nós, pois Nabucodonosor, rei de Babilônia, faz guerra contra nós; para que o SENHOR opere conosco conforme todas as suas obras maravilhosas, e o faça retirar-se de nós.
3 Ṣùgbọ́n Jeremiah dáhùn wí pé, “Sọ fún Sedekiah,
3 Então disse-lhes Jeremias: Desta forma direis a Zedequias.
4 ‘Èyí ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli wí, Èmi fẹ́ kọjú idà tí ó wà lọ́wọ́ yín sí yín, èyí tí ẹ̀ ń lò láti bá ọba àti àwọn ará Babeli tí wọ́n wà lẹ́yìn odi jà, Èmi yóò sì kó wọn jọ sínú ìlú yìí.
4 Assim diz o SENHOR Deus de Israel: Eis que eu farei retroceder as armas de guerra que estão em vossas mãos, com as quais vós lutais contra o rei de Babilônia, e contra os caldeus, que vos sitiam do lado de fora dos muros, e eu os reunirei no meio desta cidade.
5 Èmi gan an yóò sì bá yín jà pẹ̀lú ohun ìjà olóró nínú ìbínú àti ìrunú líle.
5 E eu lutarei contra vós com mão estendida, e com braço forte, e em ira, e em fúria, e em grande cólera.
6 Èmi yóò sì lu gbogbo ìlú yìí, ènìyàn àti ẹranko, gbogbo wọn ni àjàkálẹ̀-ààrùn yóò kọlù tí wọn yóò sì kú.
6 E eu afligirei os habitantes desta cidade, tanto o homem quanto o animal. Eles morrerão por causa de uma grande peste.
7 Olúwa sọ pé lẹ́yìn èyí, èmi yóò fi Sedekiah ọba Juda, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àti àwọn ènìyàn, àti àwọn tí ó kù ní ìlú yìí lọ́wọ́ àjàkálẹ̀-ààrùn àti lọ́wọ́ idà, àti lọ́wọ́ ìyàn; èmi yóò fi wọ́n lé Nebukadnessari ọba Babeli lọ́wọ́, àti lé ọwọ́ àwọn ọ̀tá wọn, àti lé ọwọ́ àwọn tí ń lépa ẹ̀mí wọn, òun yóò sì fi ojú idà pa wọ́n, kì yóò sì dá wọn sí, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò ní ìyọ́nú tàbí ṣàánú wọn.’
7 E após isso, diz o SENHOR, eu entregarei Zedequias, rei de Judá, e os seus servos, e o povo, e os que nesta cidade restarem da peste, da espada, e da fome, na mão de Nabucodonosor, rei de Babilônia, e na mão de seus inimigos, e na mão daqueles que buscam suas vidas. E ele os atingirá com a lâmina da espada. Ele não os poupará, nem terá piedade, nem terá misericórdia.
8 “Síwájú sí i, sọ fún àwọn ènìyàn, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó sọ: Wò ó, Èmi ń fi ọ̀nà ìyè àti ikú hàn yín.
8 E para este povo tu dirás: Assim diz o SENHOR: Eis que eu coloco perante vós o caminho de vida, e o caminho de morte.
9 Ẹnikẹ́ni tí ó bá dúró sí ìlú yìí yóò ti ipa idà, ìyàn tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn kú. Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá jáde tí ó sì jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún àwọn Babeli tí ó ń lépa yín yóò sì yè. Òun yóò sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀.
9 Aquele que permanecer nesta cidade morrerá pela espada, e pela fome, e pela peste. Porém aquele que sair e for para os caldeus que vos sitiam, viverá, e sua vida será para ele como um despojo.
10 Mo ti pinnu láti jẹ ìlú yìí ní yà, ni Olúwa wí. A ó sì gbé e fún ọba Babeli, yóò sì run ún pẹ̀lú iná.’
10 Porque eu coloquei a minha face contra esta cidade para o mal, e não para o bem, diz o SENHOR. Ela será dada na mão do rei de Babilônia, e ele a queimará a fogo.
11 “Ẹ̀wẹ̀, wí fún ìdílé ọba Juda pé, ‘Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
11 E com relação à casa do rei de Judá, dize: Ouvi vós a palavra do SENHOR.
12 Ilé Dafidi èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ:
12 Ó casa de Davi, assim diz o SENHOR: Executai juízo na manhã, e livrai aquele que é espoliado da mão do opressor, para que a minha fúria não saia como fogo, e queime de tal modo que ninguém possa apagá-lo, por causa do mal de vossos feitos.
13 Mo kẹ̀yìn sí ọ, Jerusalẹmu,
13 Eis que eu sou contra ti, diz o SENHOR, ó habitante do vale, e rocha da planície, que dizeis: Quem irá descer contra nós? Ou quem irá adentrar nossas habitações?
14 Èmi yóò jẹ ọ ní ìyà gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀
14 Porém, eu vos punirei conforme o fruto de vossos feitos, diz o SENHOR, e atearei um fogo na sua floresta, e ele devorará todas as coisas em todas as direções ao seu redor.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jeremias 21, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.