Jeremias 11

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Jeremiah wá:
1 Palavra que veio a Jeremias da parte do SENHOR, dizendo:
2 “Fetísílẹ̀ sí ọ̀rọ̀ májẹ̀mú yìí, kí o sì sọ wọ́n fún àwọn ènìyàn Juda, àti gbogbo àwọn tó ń gbé ni Jerusalẹmu.
2 Ouvi vós as palavras deste pacto, e falai aos homens de Judá e aos habitantes de Jerusalém.
3 Sọ fún wọn wí pé èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Ègbé ni fún ẹni náà tí kò pa ọ̀rọ̀ májẹ̀mú yìí mọ́.
3 E dize-lhes: Assim diz o SENHOR Deus de Israel: Amaldiçoado seja o homem que não obedecer as palavras deste pacto.
4 Àwọn májẹ̀mú tí mo pàṣẹ fún àwọn baba ńlá yín, nígbà tí mo mú wọn jáde láti Ejibiti, láti inú iná alágbẹ̀dẹ wá.’ Mo wí pé, ‘Ẹ gbọ́ tèmi, kí ẹ sì ṣe ohun gbogbo tí mo pàṣẹ fún un yín. Ẹ̀yin ó sì jẹ́ ènìyàn mi, Èmi ó sì jẹ́ Ọlọ́run yín.
4 Que ordenei aos vossos pais no dia em que eu os tirei da terra do Egito, da fornalha de ferro, dizendo: Obedecei à minha voz, e fazei conforme tudo que eu vos ordenei. Então vós sereis meu povo, e eu serei vosso Deus.
5 Nígbà náà ni Èmi ó sì mú ìlérí tí mo búra fún àwọn baba ńlá yín ṣẹ; láti fún wọn ní ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti fún oyin,’ ilẹ̀ tí ẹ ní lónìí.”
5 Para que eu possa realizar completamente o juramento que fiz aos vossos pais, de dar-lhes uma terra que mana leite e mel, como é neste dia. Então eu respondi, e disse: Que assim seja, ó SENHOR.
6 Olúwa wí fún mi pé, “Kéde gbogbo ọ̀rọ̀ yìí ní àwọn ìlú Juda àti ní gbogbo òpópónà ìgboro Jerusalẹmu pé, ‘Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ májẹ̀mú yìí, kí ẹ sì se wọn.
6 Então o SENHOR me disse: Proclama todas estas palavras nas cidades de Judá, e nas ruas de Jerusalém, dizendo: Ouvi vós as palavras deste pacto, e cumpri-as.
7 Láti ìgbà tí mo ti mú àwọn baba yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá títí di òní, mo kìlọ̀ fún wọn lọ́pọ̀ ìgbà wí pé, “Ẹ gbọ́ tèmi.”
7 Pois eu seriamente adverti a vossos pais no dia em que eu os tirei da terra do Egito, até este dia, madrugando e advertindo, dizendo: Obedecei à minha voz.
8 Ṣùgbọ́n wọn kò gbọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò kọbi ara sí i dípò èyí wọ́n tẹ̀síwájú ni agídí ọkàn wọn. Mo sì mú gbogbo ègún inú májẹ̀mú tí mo ti ṣèlérí, tí mo sì ti pàṣẹ fún wọn láti tẹ̀lé, tí wọn kò tẹ̀lé wa sórí wọn.’ ”
8 Contudo eles não obedeceram, nem inclinaram os seus ouvidos, porém andaram cada um na imaginação do seu coração malvado. Portanto eu trarei sobre eles todas as palavras deste pacto, as quais eu ordenei que lhes cumprissem, porém eles não o fizeram.
9 Olúwa sì wí fún mi pé, “Ọ̀tẹ̀ kan wà láàrín àwọn ará Juda àti àwọn tí ń gbé ní Jerusalẹmu.
9 E o SENHOR disse para mim: Há uma conspiração entre os homens de Judá, e entre os habitantes de Jerusalém.
10 Wọ́n ti padà sí ìdí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba ńlá wọn tí wọn kọ̀ láti tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ mi, wọ́n ti tẹ̀lé àwọn ọlọ́run mìíràn láti sìn wọ́n. Ilé Israẹli àti ilé Juda ti ba májẹ̀mú tí mo dá pẹ̀lú àwọn baba ńlá wọn jẹ́.
10 Eles retornaram às iniquidades dos seus antepassados, os quais se recusaram a ouvir minhas palavras, e eles se foram após outros deuses para os servirem. A casa de Israel e a casa de Judá quebraram o meu pacto, que estabeleci com os seus pais.
11 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Èmi yóò mu ibi tí wọn kò ní le è yẹ̀ wá sórí wọn, bí wọ́n tilẹ̀ ké pè mí èmi kì yóò fetí sí igbe wọn.
11 Portanto assim diz o SENHOR: Eis que eu trarei o mal sobre eles, e não serão capazes de escapar. Ainda que eles clamem a mim, eu não os escutarei.
12 Àwọn ìlú Juda àti àwọn ará Jerusalẹmu yóò lọ kégbe sí àwọn òrìṣà tí wọ́n ń sun tùràrí sí; àwọn òrìṣà náà kò ní ràn wọ́n lọ́wọ́ ní ìgbà tí ìpọ́njú náà bá dé.
12 Então as cidades de Judá e os habitantes de Jerusalém, irão e clamarão aos deuses a quem eles oferecem incenso. Porém eles não os salvarão de modo algum no tempo da sua aflição.
13 Ìwọ Juda, bí iye àwọn ìlú rẹ, bẹ́ẹ̀ iye àwọn òrìṣà rẹ; bẹ́ẹ̀ ni iye pẹpẹ tí ẹ̀yin ti tẹ́ fún sísun tùràrí Baali ohun ìtìjú n nì ṣe pọ̀ bí iye òpópónà tí ó wà ní Jerusalẹmu.’
13 Pois conforme o número de tuas cidades eram teus deuses, ó Judá, e conforme o número das ruas de Jerusalém levantaste altares para aquela coisa vergonhosa, até altares para queimar incenso a Baal.
14 “Má ṣe gbàdúrà fún àwọn ènìyàn wọ̀nyí tàbí kí o bẹ̀bẹ̀ fún wọn, nítorí pé, Èmi kì yóò dẹtí sí wọn nígbà tí wọ́n bá ké pè mí ní ìgbà ìpọ́njú.
14 Portanto, não ores por este povo, nem ergas um clamor ou oração por eles. Pois eu não os ouvirei quando clamarem a mim pela sua aflição.
15 “Kí ni olùfẹ́ mi ní í ṣe ní tẹmpili mi,
15 O que minha amada faz em minha casa, visto que ela forjou lascívia com muitos? E a carne santa passou de ti? Quando tu fazes o mal, então tu te regozijas.
16 Olúwa pè ọ́ ní igi olifi
16 O SENHOR chamou teu nome: Uma oliveira verde, bela e de fruto excelente. Com o barulho de um grande tumulto, ele ateou fogo ao redor dela, e se quebraram os seus ramos.
17 Olúwa àwọn ọmọ-ogun tí ó dá ọ ti kéde ibi sí ọ, nítorí ilé Israẹli àti Juda ti ṣe ohun ibi, wọ́n sì ti mú inú bí mi, wọ́n ti ru ìbínú mi sókè nípa sísun tùràrí si Baali.
17 Pois o SENHOR dos Exércitos, que te plantou, pronunciou o mal contra ti, por causa do mal da casa de Israel, e da casa de Judá, o qual fazem contra si mesmos, para me provocar a ira ao oferecer incenso a Baal.
18 Nítorí Olúwa fi ọ̀tẹ̀ wọn hàn mí mo mọ̀ ọ́n; nítorí ní àsìkò náà ó fi ohun tí wọ́n ń ṣe hàn mí.
18 E o SENHOR deu-me conhecimento disto, e eu sei isto. Então me mostraste os seus feitos.
19 Mo ti dàbí ọ̀dọ́-àgùntàn jẹ́ẹ́jẹ́ tí a mú lọ fún pípa; n kò mọ̀ pé wọ́n ti gbìmọ̀ búburú sí mi wí pé:
19 Porém eu era como um cordeiro ou um boi que é levado ao matadouro, e eu não sabia que eles tinham planejado intentos malignos contra mim, dizendo: Destruamos a árvore com o seu fruto, e cortemo-lo da terra dos viventes, para que o nome não seja mais lembrado.
20 Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun,
20 Porém, ó SENHOR dos Exércitos, que julgas justamente, que provas os rins e o coração, permita-me ver a tua vingança sobre eles, pois a ti revelei minha causa.
21 “Nítorí náà, èyí ni ohun tí Ọlọ́run sọ nípa àwọn arákùnrin Anatoti tí wọ́n ń lépa ẹ̀mí rẹ̀, tí wọ́n ń wí pé, ‘Má ṣe sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ Olúwa, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ ìwọ ó kú láti ọwọ́ wa.’
21 Portanto assim diz o SENHOR acerca dos homens de Anatote, que buscam tua vida, dizendo: Não profetizes no nome do SENHOR, para que tu não morras por nossa mão.
22 Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ pé, ‘Èmi yóò fì ìyà jẹ wọ́n, àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin wọn yóò tipasẹ̀ idà kú, ìyàn yóò pa àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn.
22 Portanto assim diz o SENHOR dos Exércitos: Eis que eu os punirei; os homens jovens morrerão pela espada; os seus filhos e as suas filhas morrerão de fome.
23 Kò ní ṣẹ́kù ohunkóhun sílẹ̀ fún wọn nítorí èmi yóò mú ibi wá sórí àwọn ènìyàn Anatoti ní ọdún ìbẹ̀wò wọn.’ ”
23 E não haverá remanescente deles, pois eu trarei o mal sobre os homens de Anatote, até o ano de sua visitação.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jeremias 11, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.