Jó 42

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Nígbà náà ní Jobu dá Olúwa lóhùn, ó sì wí pé,
1 Então Jó respondeu ao SENHOR, e disse:
2 “Èmi mọ̀ pé, ìwọ lè e ṣe ohun gbogbo,
2 Eu sei que tu podes fazer qualquer coisa, e que nenhum pensamento pode lhe ser impedido.
3 Ìwọ béèrè, ta ni ẹni tí ń fi ìgbìmọ̀ pamọ́ láìní ìmọ̀?
3 Quem é este, que esconde o conselho sem conhecimento? Por isso proferi o que não entendia; coisas maravilhosas demais para mim, as quais eu não sabia.
4 “Ìwọ wí pé, ‘Gbọ́ tèmi báyìí,
4 Ouve, eu te suplico, e eu falarei; exigirei de ti, e tu, declara-te a mim.
5 Etí mi sì ti gbọ́ nípa rẹ,
5 Eu tinha ouvido de ti com os ouvidos; mas agora meus olhos te veem.
6 Ǹjẹ́ nítorí náà èmi kórìíra ara mi,
6 Portanto, abomino-me e arrependo-me em pó e cinzas.
7 Bẹ́ẹ̀ ó sì rí, lẹ́yìn ìgbà tí Olúwa ti sọ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún Jobu, Olúwa sì wí fún Elifasi, ará Temani pé, mo bínú sí ọ, àti sí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ méjèèjì, nítorí pé ẹ̀yin kò sọ̀rọ̀, ní ti èmi, ohun tí ó tọ́, bí Jobu ìránṣẹ́ mi ti sọ.
7 E assim foi que, depois do SENHOR ter falado estas palavras a Jó, o SENHOR disse a Elifaz, o temanita: A minha ira se acendeu contra ti, e contra os teus dois amigos, porque não falastes de mim aquilo que é certo, como o meu servo Jó.
8 Nítorí náà, ẹ mú akọ ẹgbọrọ màlúù méje, àti àgbò méje, kí ẹ sì tọ̀ Jobu ìránṣẹ́ mi lọ, kí ẹ sì fi rú ẹbọ sísun fún ara yín; Jobu ìránṣẹ́ mi yóò sì gbàdúrà fún yin; nítorí pé àdúrà rẹ̀ ní èmi yóò gbà; kí èmi kí ó má ba ṣe si yín bí ìṣìnà yín, ní ti pé ẹ̀yin kò sọ̀rọ̀ ohun tí ó tọ́ sí mi bi Jobu ìránṣẹ́ mi ti ṣe.
8 Portanto, tomai para vós agora sete novilhos e sete carneiros, e ide até meu servo Jó, e oferecei por vós mesmos uma oferta queimada; e o meu servo Jó orará por vós; por ele eu o aceitarei, para que eu não lide com vós conforme a vossa loucura; porque vós não falastes de mim aquilo o que é certo, como o meu servo Jó.
9 Bẹ́ẹ̀ ní Elifasi, ara Temani, àti Bilidadi, ará Ṣuhi, àti Sofari, ará Naama lọ, wọ́n sì ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún wọn. Olúwa sì gbọ́ àdúrà Jobu.
9 Então Elifaz, o temanita, e Bildade, o suíta, e Zofar, o naamatita, foram e fizeram de acordo com o que o SENHOR lhes ordenou; o SENHOR também aceitou Jó.
10 Olúwa sì yí ìgbèkùn Jobu padà, nígbà tí ó gbàdúrà fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀; Olúwa sì bùsi ohun gbogbo ti Jobu ní rí ní ìṣẹ́po méjì ohun tí ó ní tẹ́lẹ̀ rí.
10 E o SENHOR mudou o cativeiro de Jó quando ele orava por seus amigos; também o SENHOR deu a Jó duas vezes mais do que ele tinha antes.
11 Nígbà náà ní gbogbo àwọn arákùnrin rẹ̀, àti gbogbo àwọn arábìnrin rẹ̀, àti gbogbo àwọn tí ó ti ṣe ojúlùmọ̀ rẹ̀ rí; wọ́n bá a jẹun nínú ilé rẹ̀. Wọ́n sì ṣe ìdárò rẹ̀, wọ́n sì ṣìpẹ̀ fún un nítorí ibi gbogbo tí Olúwa ti mú bá a. Olúkúlùkù ènìyàn pẹ̀lú sì fún un ní ẹyọ owó kọ̀ọ̀kan àti olúkúlùkù ni òrùka wúrà etí kọ̀ọ̀kan.
11 Então vieram a ele todos os seus irmãos, e todas as suas irmãs, e todos os que antes o conheceram, e comeram com ele pão em sua casa, e se lamentaram com ele, e o consolaram acerca de todo o mal que o SENHOR havia trazido sobre ele; cada homem também lhe deu uma peça de dinheiro, e cada um, um brinco de ouro.
12 Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa bùkún ìgbẹ̀yìn Jobu ju ìṣáájú rẹ̀ lọ; ẹgbàá méje (14,000) àgùntàn, ẹgbẹ̀rún mẹ́fà (6,000) ìbákasẹ, àti ẹgbẹ̀rún (1,000) àjàgà ọ̀dá màlúù, àti ẹgbẹ̀rún (1,000) abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
12 Assim o SENHOR abençoou os últimos dias de Jó mais do que o seu começo; porque ele teve catorze mil ovelhas, seis mil camelos, mil juntas de bois e mil jumentas.
13 Ó sì ní ọmọkùnrin méje àti ọmọbìnrin mẹ́ta.
13 Ele também teve sete filhos e três filhas.
14 Ó sì sọ orúkọ àkọ́bí ní Jemima, àti orúkọ èkejì ni Kesia àti orúkọ ẹ̀kẹta ní Kereni-Happuki.
14 E chamou o nome da primeira de Jemima, e o nome da segunda, Quezia, e o nome da terceira, Quéren-Hapuque.
15 Àti ní gbogbo ilẹ̀ náà, a kò rí obìnrin tí ó ní ẹwà bí ọmọ Jobu; baba wọ́n sì pínlẹ̀ fún wọn nínú àwọn arákùnrin wọn.
15 E em toda a terra não se achavam mulheres tão formosas como as filhas de Jó; e seu pai lhes deu herança entre seus irmãos.
16 Lẹ́yìn èyí Jobu wà ní ayé ní ogóje ọdún, ó sì rí àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin àti ọmọ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, àní ìran mẹ́rin.
16 Depois disto viveu Jó cento e quarenta anos; e viu seus filhos, e os filhos de seus filhos até quatro gerações.
17 Bẹ́ẹ̀ ni Jobu kú, ó gbó, ó sì kún fún ọjọ́ púpọ̀.
17 Então morreu Jó, sendo velho e farto de dias.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jó 42, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.