Jó 2

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Ó sì tún di ọjọ́ kan nígbà tí àwọn ọmọ Ọlọ́run wá síwájú Olúwa, Satani sì wá pẹ̀lú wọn láti pe níwájú Olúwa.
1 Novamente, houve um dia quando os filhos de Deus vieram apresentar-se diante do SENHOR, Satanás veio também entre eles para apresentar-se diante do SENHOR.
2 Olúwa sì bi Satani pé, “Níbo ni ìwọ ti wá?”
2 E o SENHOR disse a Satanás: De onde tu vens? E Satanás respondeu ao SENHOR, e disse: De ir para lá e para cá na terra, e de nela andar para cima e para baixo.
3 Olúwa sì wí fún Satani pé, “Ìwọ ha kíyèsi Jobu ìránṣẹ́ mi, pé, kò sí ẹni tí ó dàbí rẹ̀ ní ayé, ọkùnrin tí ń ṣe olóòtítọ́ tí ó sì dúró ṣinṣin, ẹni tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run, tí ó sì kórìíra ìwà búburú, bẹ́ẹ̀ ni ó sì di ìwà òtítọ́ rẹ̀ mu ṣinṣin, bí ìwọ tilẹ̀ ti dẹ mí sí i láti run ún láìnídìí.”
3 E o SENHOR disse a Satanás: Tu consideraste o meu servo Jó, que não há ninguém como ele na terra, homem perfeito e justo, que teme a Deus e se afasta do mal, e que ainda se apega à sua integridade, apesar de que me incitaste contra ele, para destruí-lo sem causa.
4 Satani sì dá Olúwa lóhùn wí pé, “Awọ fún awọ; àní ohun gbogbo tí ènìyàn ní, òun ni yóò fi ra ẹ̀mí rẹ̀.
4 E Satanás respondeu ao SENHOR, e disse: Pele por pele, sim; tudo o que um homem tem ele dará por sua vida.
5 Ṣùgbọ́n nawọ́ rẹ nísinsin yìí, kí ó tọ́ egungun rẹ̀ àti ara rẹ̀, bí kì yóò sì bọ́hùn ní ojú rẹ.”
5 Porém, estende tua mão agora, e toca-lhe os ossos, e a carne, e ele te amaldiçoará diante de tua face.
6 Olúwa sì wí fún Satani pé, “Wò ó, ó ń bẹ ní ìkáwọ́ rẹ, ṣùgbọ́n dá ẹ̀mí rẹ̀ sí.”
6 E o SENHOR disse a Satanás: Eis que ele está na tua mão; mas poupa-lhe a vida.
7 Bẹ́ẹ̀ ni Satani jáde lọ kúrò níwájú Olúwa, ó sì sọ Jobu ní oówo kíkankíkan láti àtẹ́lẹsẹ̀ títí dé àtàrí rẹ̀.
7 Então Satanás retirou-se da presença do SENHOR, e feriu Jó com úlceras malignas desde a sola de seu pé até sua coroa.
8 Ó sì mú àpáàdì, ó fi ń họ ara rẹ̀, ó sì jókòó nínú eérú.
8 E ele tomando para si um caco, se raspava com ele; estando assentado entre as cinzas.
9 Nígbà náà ni aya rẹ̀ wí fún un pé, “Ìwọ di ìwà òtítọ́ mú síbẹ̀! Bú Ọlọ́run, kí ó sì kú!”
9 Então disse sua esposa a ele: Ainda reténs tua integridade? Amaldiçoa a Deus, e morre.
10 Ṣùgbọ́n ó dá a lóhùn pé, “Ìwọ sọ̀rọ̀ bí ọ̀kan lára àwọn aṣiwèrè obìnrin ti í sọ̀rọ̀; há bà! Àwa yóò ha gba ìre lọ́wọ́ Ọlọ́run, kí a má sì gba ibi?”
10 Mas ele disse a ela: Tu falas como costumam falar as mulheres tolas. Se receberemos o bem da mão de Deus, não receberemos o mal? Em tudo isto não pecou Jó com os seus lábios.
11 Nígbà tí àwọn ọ̀rẹ́ Jobu mẹ́ta gbúròó gbogbo ibi tí ó bá a, wọ́n wá, olúkúlùkù láti ibùjókòó rẹ̀; Elifasi, ara Temani àti Bilidadi, ará Ṣuhi, àti Sofari, ará Naama: nítorí pé wọ́n ti dájọ́ ìpàdé pọ̀ láti bá a ṣọ̀fọ̀, àti láti ṣìpẹ̀ fún un.
11 Então, quando os três amigos de Jó ouviram sobre todo este mal que lhe sobreviera, cada um veio de seu próprio lugar: Elifaz, o temanita, e Bildade, o suíta, e Zofar, o naamatita; porque haviam concordado em vir para prantear com ele e consolá-lo.
12 Nígbà tí wọ́n gbójú wọn wò ní òkèrè réré, tí wọ́n kò sì mọ̀ ọ́n, wọ́n gbé ohùn wọn sókè, wọ́n sọkún: olúkúlùkù sì fa aṣọ ìgúnwà rẹ̀ ya, wọ́n sì ku erùpẹ̀ sí ojú ọ̀run, wọ́n sì tẹ́ orí gbà á.
12 E quando eles levantaram seus olhos de longe, não o conheceram, levantaram sua voz e choraram, e cada um rasgou o seu manto e lançou pó sobre as suas cabeças em direção ao céu.
13 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n jókòó tì í ní inú erùpẹ̀ ní ọjọ́ méje ti ọ̀sán ti òru, ẹnikẹ́ni kò sì bá a sọ ọ̀rọ̀ kan, nítorí tí wọ́n ti rí i pé ìbànújẹ́ rẹ̀ pọ̀ jọjọ.
13 Então, assentaram-se com ele no chão, durante sete dias e sete noites; e ninguém lhe falou uma palavra, porque eles viram que sua dor era muito grande.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jó 2, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.