Jó 17

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 “Ẹ̀mí mi bàjẹ́,

2 Nítòótọ́ àwọn ẹlẹ́yà wà lọ́dọ̀ mi,

3 “Fi fún mi Olúwa, ìlérí tí ìwọ fẹ́;

4 Nítorí pé ìwọ ti sé wọ́n láyà kúrò nínú òye;

5 Ẹni tí ó sọ ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn dídún fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ fún èrè,

6 “Ọlọ́run ti sọ mi di ẹni òwe fún àwọn ènìyàn;

7 Ojú mí ṣú bàìbàì nítorí ìbìnújẹ́,

8 Àwọn olódodo yóò yanu sí èyí,

9 Olódodo pẹ̀lú yóò di ọ̀nà rẹ̀ mú,

10 “Ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti gbogbo yín,

11 Ọjọ́ tí èmi ti kọjá, ìrò mi ti fà yá,

12 Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń ṣọ́ òru di ọ̀sán;

13 Bí mo tilẹ̀ ní ìrètí, ipò òku ní ilé mi;

14 Èmi ti wí fún ìdíbàjẹ́ pé, ìwọ ni baba mi,

15 ìrètí mi ha dà nísinsin yìí?

16 Yóò sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ipò òkú,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jó 17, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.