1 “Ẹ̀mí mi bàjẹ́,
2 Nítòótọ́ àwọn ẹlẹ́yà wà lọ́dọ̀ mi,
3 “Fi fún mi Olúwa, ìlérí tí ìwọ fẹ́;
4 Nítorí pé ìwọ ti sé wọ́n láyà kúrò nínú òye;
5 Ẹni tí ó sọ ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn dídún fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ fún èrè,
6 “Ọlọ́run ti sọ mi di ẹni òwe fún àwọn ènìyàn;
7 Ojú mí ṣú bàìbàì nítorí ìbìnújẹ́,
8 Àwọn olódodo yóò yanu sí èyí,
9 Olódodo pẹ̀lú yóò di ọ̀nà rẹ̀ mú,
10 “Ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti gbogbo yín,
11 Ọjọ́ tí èmi ti kọjá, ìrò mi ti fà yá,
12 Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń ṣọ́ òru di ọ̀sán;
13 Bí mo tilẹ̀ ní ìrètí, ipò òku ní ilé mi;
14 Èmi ti wí fún ìdíbàjẹ́ pé, ìwọ ni baba mi,
15 ìrètí mi ha dà nísinsin yìí?
16 Yóò sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ipò òkú,