João 7
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí Jesu ń rìn ní Galili, nítorí tí kò fẹ́ rìn ní Judea, nítorí àwọn Júù ń wá a láti pa.
1 Nati ufunamaim Jesu Galilee wanawanan run titit remor in, men kok au Judea tan anayabin Jew hai ukwarih hima hikakaif hitarab tamorob isan.
2 Àjọ àwọn Júù tí í ṣe àjọ àgọ́ súnmọ́ etílé tan.
2 Baise Jew sabuw Yagama Sis ana hiyuw aa ana veya i nabiyubin,
3 Nítorí náà, àwọn arákùnrin rẹ̀ wí fún un pé, “Lọ kúrò níhìn-ín yìí, kí o sì lọ sí Judea, kí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ pẹ̀lú lè fi iṣẹ́ rẹ hàn fún aráyé.
3 Imih Jesu taitin hi’o, “O boro efan iti inihamiy naatu inan Judea inatit, saise a bai’ufununayah bowabow gewasih abistan kusisinaf hina’itin.
4 Nítorí pé kò sí ẹnikẹ́ni tí í ṣe ohunkóhun níkọ̀kọ̀, tí òun tìkára rẹ̀ sì ń fẹ́ kí a mọ òun ní gbangba. Bí ìwọ bá ń ṣe nǹkan wọ̀nyí, fi ara rẹ hàn fún aráyé.”
4 Anayabin orot yait sabuw etei su’ubin isan boro men wa’iwa’iramaim nabowamih. Baise bebeyanamaim nabow hina’itin. Imih a bowabow bebeyanamaim inabow tafaram tutufin etei ini’obaiyih hina’itin.”
5 Nítorí pé àwọn arákùnrin rẹ̀ pàápàá kò tilẹ̀ gbà á gbọ́.
5 I taiyuwin taitin men hitumitum, imih iti tur hi’o.
6 Nítorí náà ni Jesu wí fún wọn pé, “Àkókò gan an fún mi kò tí ì dé; fún ẹ̀yin, gbogbo àkókò ni ó dára fún yín.
6 Naatu Jesu iuwih eo, “Ayu au veya i men na tit, baise kwa a veya i mar etei bobotawiyen inu’in.
7 Ayé kò lè kórìíra yín; ṣùgbọ́n èmi ni ó kórìíra, nítorí tí mo jẹ́rìí gbé é pé, iṣẹ́ rẹ̀ burú.
7 Sabuw kwa boro men hinifutuwi, baise ayu boro hinifutuwu, anayabin ayu mar etei sabuw hai kakafih ao’orerereb.
8 Ẹ̀yin ẹ gòkè lọ sí àjọ yìí, èmi kì yóò tí ì gòkè lọ sí àjọ yìí; nítorí tí àkókò mi kò ì tí ì dé.”
8 Hiyuw isan kwa akis kwanan ayu men bairit tanan, anayabin ayu au veya anababatun i men na tit.”
9 Nígbà tí ó ti sọ nǹkan wọ̀nyí fún wọn tan, ó dúró ní Galili síbẹ̀.
9 Iti na’atube eo, i Galilee wanawananamaim ma.
10 Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn arákùnrin rẹ̀ gòkè lọ tan, nígbà náà ni òun sì gòkè lọ sí àjọ náà pẹ̀lú, kì í ṣe ní gbangba, ṣùgbọ́n bí ẹni pé níkọ̀kọ̀.
10 Taitin hiyuw isan hiyen hinan, i auman ufuh yen in, men bebeyanamaim in baise i wa’iwa’iramaim in.
11 Nígbà náà ni àwọn Júù sì ń wá a kiri nígbà àjọ wí pé, “Níbo ni ó wà?”
11 Nati hiyuw wanawanan Jew hai ukwarih Jesu isan hinuwet sabuw hibabatiyih, “Iti orot menamaim ema’am?”
12 Ìkùnsínú púpọ̀ sì wà láàrín àwọn ìjọ ènìyàn nítorí rẹ̀, nítorí àwọn kan wí pé, “Ènìyàn rere ní í ṣe.”
12 Sabuw wanawanahimaim baitarsibesib busuruf ra’at. Sabuw afa hi’o, “I orot gewasin,” afa hi’o, “Aiyabin i sabuw ebifufuwih?”
13 Ṣùgbọ́n kò sí ẹnìkan tí ó sọ̀rọ̀ rẹ̀ ní gbangba nítorí ìbẹ̀rù àwọn Júù.
13 Baise men yait ta boro fanan aumetawat isan hitao, anayabin Jew ukwarih isah hibir.
14 Nígbà tí àjọ dé àárín; Jesu gòkè lọ sí tẹmpili ó sì ń kọ́ni.
14 Hiyuw hi’aa na biyanfoun, Jesu na Tafaror Bar run naatu bai’obaiyen busuruf.
15 Ẹnu sì ya àwọn Júù, wọ́n wí pé, “Ọkùnrin yìí ti ṣe mọ ìwé, nígbà tí kò kọ́ ẹ̀kọ́?”
15 Jew hai ukwarih hifofofor men kafai ta naatu hi’o, “Iti orot menamaim kirum iti so’ob bai?”
16 Jesu dáhùn, ó sì wí pé, “Ẹ̀kọ́ mi kì í ṣe tèmi, bí kò ṣe ti ẹni tí ó rán mi.
16 Imaibo Jesu iyafutih eo, “Bai’obaiyen ayu abi’obaiyi i men ayu nowau, baise God ayu biyafaru i nowan.
17 Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ láti ṣe ìfẹ́ rẹ̀ yóò mọ̀ ní ti ẹ̀kọ́ náà, bí ìbá ṣe ti Ọlọ́run, tàbí bí èmi bá sọ ti ara mi.
17 O Yait ta God anakok kusisinaf boro inaso’ob ayu au bai’obaiyen i Godane enan, ai ayu taiyuwu au fairamaim ao’o.
18 Ẹni tí ń sọ ti ara rẹ̀ ń wá ògo ara rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹni tí ń wá ògo ẹni tí ó rán an, òun ni olóòtítọ́, kò sì sí àìṣòdodo nínú rẹ̀.
18 Yait taiyuwin ana fairamaim eo’o, i taiyuwin ana gewasin bain isan enunuwih, baise orot yait God ayu iyafaru anan ana gewasin enunuwih nati orot i turobe, i wanawananamaim men baifuwen ema’am.
19 Mose kò ha fi òfin fún yín, kò sí ẹnikẹ́ni nínú yín tí ó pa òfin náà mọ́? Èéṣe tí ẹ̀yin fi ń wá ọ̀nà láti pa mí?”
19 Moses ofafar kwa it ai en? Aisim ofafafar men kwabi’ufunun naatu ayu rabu morobomih kwabiwa’an?”
20 Ìjọ ènìyàn dáhùn, wọ́n sì wí pé, “Ìwọ ní ẹ̀mí èṣù, ta ni ń wá ọ̀nà láti pa ọ́?”
20 Sabuw hiya’afut hi’o, “O wanawan i demon tema’am. Yait o asabunimih ebiwa’an?”
21 Jesu dáhùn ó sì wí fún wọn pé, “Kìkì iṣẹ́ àmì kan ni mo ṣe, ẹnu sì ya gbogbo yín.
21 Jesu iya’afutih eo, “Ayu ina’inan ta’imon asinaf kwa’itin naatu kwaifofor men kafaita.
22 Síbẹ̀, nítorí pé Mose fi ìkọlà fún yín (kò tilẹ̀ kúkú wá láti ọ̀dọ̀ Mose bí kò ṣe láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá yín); nítorí náà ẹ sì ń kọ ènìyàn ní ilà ní ọjọ́ ìsinmi.
22 Moses uwi natunat oro’orot Baiyariri hai veya’amaim hai ar, mo’oh kwa’afuw, nati i men Mosesine na, nati i kwa a’agir wabih gagamihine na. Imih kwa kek oro’orot hai ar mo’oh kwa’a’afuw.
23 Bí ènìyàn bá ń gba ìkọlà ní ọjọ́ ìsinmi, kí a má ba à rú òfin Mose, ẹ ha ti ṣe ń bínú sí mi, nítorí mo mú ènìyàn kan láradá ní ọjọ́ ìsinmi?
23 Kwa Baiyarir ana veya’amaim kek orot ana ar mo’on kwana’a’afuw nati Moses ana ofafar i men kwa’a’astu’ub, aisimamih ayu Baiyarir Ana Veya orot biyan tutufin abiyawas isan kwa ya esoso’ar?
24 Ẹ má ṣe ìdájọ́ nípa ti ara, ṣùgbọ́n ẹ máa ṣe ìdájọ́ òdodo.”
24 Men ufun ana’itininamaim sabuw kwanibabatiyih, baise a baibabatiyen i turobe’emaim kwanibatiyih.”
25 Nígbà náà ni àwọn kan nínú àwọn ará Jerusalẹmu wí pé, “Ẹni tí wọ́n ń wá ọ̀nà láti pa kọ́ yìí?
25 Nati isan Jerusalem sabuw afa hibusuruf hibatebat hi’o, “Orotoban iti i boun rabin morobomih ana ef tenunuwet?
26 Sì wò ó, ó ń sọ̀rọ̀ ní gbangba, wọn kò sì wí nǹkan kan sí i. Àwọn olórí ha mọ̀ nítòótọ́ pé, èyí ni Kristi náà?
26 Kwa’itin iban iti bebeyanamaim eo’o, naatu i men tur ta isan te’eo’omih. Kwa kwanotanot sabuw ukwarihiban hiso’ob gewas iti orot i turobe Rourubinen?
27 Ṣùgbọ́n àwa mọ ibi tí ọkùnrin yí gbé ti wá, ṣùgbọ́n nígbà tí Kristi bá dé, kò sí ẹni tí yóò mọ ibi tí ó gbé ti wá.”
27 Baise iti orot menane nan i aki aso’ob; Rourubinen nanan anamaramaim boro men yait ta naso’ob i menane na.”
28 Nígbà náà ni Jesu kígbe ní tẹmpili bí ó ti ń kọ́ni, wí pé, “Ẹ̀yin mọ̀ mí, ẹ sì mọ ibi tí mo ti wá, èmi kò sì wá fún ara mi, ṣùgbọ́n olóòtítọ́ ni ẹni tí ó rán mi, ẹni tí ẹ̀yin kò mọ̀.
28 Imaibo Jesu Tafaror bar wanawanan ma bi’obaibiyih fanan aumetawat na’in eo, “Turobe ayu kwa kwaso’ob, naatu menane anan kwa kwaso’ob? Ayu iti anan i men taiyuwu au kok ana, baise turobe ana God ayu iyunu ana. Nati orot kwa men kwaso’ob
29 Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ ọ́n, nítorí pé lọ́dọ̀ rẹ̀ ni mo ti wá, òun ni ó rán mi.”
29 ayu asu’ub, anayabin ayu ine ana naatu i iyunu ana.”
30 Nítorí náà wọ́n ń wá ọ̀nà à ti mú un, ṣùgbọ́n kò sí ẹnìkan tí ó gbé ọwọ́ lé e, nítorí tí wákàtí rẹ̀ kò tí ì dé.
30 Nati’imaim sabuw bain fatuminamih hiwa’an, baise men yait ta biyan butubun, anayabin ana veya i men natit.
31 Ọ̀pọ̀ nínú ìjọ ènìyàn sì gbà á gbọ́, wọ́n sì wí pé, “Nígbà tí Kristi náà bá dé, yóò ha ṣe iṣẹ́ àmì jù wọ̀nyí, tí ọkùnrin yìí ti ṣe lọ?”
31 Baise rou’ay gagamin wanawanan sabuw moumurin maiyow hitumitum naatu hi’o, “Rourubinen nanan ina’inan fairih moumurihika nasinaf iti orot boro nanatabir.”
32 Àwọn Farisi gbọ́ pé, ìjọ ènìyàn ń sọ nǹkan wọ̀nyí lábẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀; àwọn Farisi àti àwọn olórí àlùfáà sì rán àwọn oníṣẹ́ lọ láti mú un.
32 Rou’ay wanawanan Jesu sawar sisinaf isan hibitarsibesib Pharisee hinowar. Basit firis gagagamih naatu Pharisee Tafaror Bar ma’utayah hiyafarih hin Jesu bain fatuminamih.
33 Nítorí náà Jesu wí fún wọn pé, “Níwọ́n ìgbà díẹ̀ ni èmi yóò wà pẹ̀lú yín, èmi yóò lọ sí ọ̀dọ̀ ẹni tí ó rán mi.
33 Imih Jesu eo, “Ayu boro men manin bairit tanama, naatu anamatabir maiye anan yait iyunu anan biyan anatit.
34 Ẹ̀yin yóò wá mi, ẹ̀yin kì yóò sì rí mi, àti ibi tí èmi bá wà, ẹ̀yin kì yóò le wà.”
34 Kwa boro ayu kwananuwuhu, baise boro men kwanatita’uru, naatu ayu menamaim anama’am, kwa boro men kwanan.”
35 Nítorí náà ni àwọn Júù ń bá ara wọn sọ pé, “Níbo ni ọkùnrin yìí yóò gbé lọ tí àwa kì yóò fi rí i? Yóò ha lọ sí àárín àwọn Helleni tí wọ́n fọ́n káàkiri, kí ó sì máa kọ́ àwọn Helleni bí.
35 Jew sabuw taiyuwih hima hi’o, “Iti orot boro menamaim nan nama naatu it men karam tanatita’ur? Ai i boro nan Greek wanawanah ata sabuw hitagey nanabin tema’am imaim nama ni’obaibiyih?
36 Ọ̀rọ̀ kín ni èyí tí ó sọ yìí, ‘Ẹ̀yin yóò wá mi, ẹ kì yóò sì rí mi,’ àti ‘Ibi tí èmi bá wà ẹ̀yin kì yóò le wà’?”
36 Kwa boro ayu isou kwananuwet baise boro men kwanatita’uru naatu ayu menamaim anama’am kwa boro men kwanan? Iti tur eo’o anayabin i abisa?”
37 Lọ́jọ́ tó kẹ́yìn, tí í ṣe ọjọ́ ńlá àjọ, Jesu dúró, ó sì kígbe wí pé, “Bí òǹgbẹ bá ń gbẹ ẹnikẹ́ni, kí ó tọ̀ mí wá, kí ó sì mu.
37 Hiyuw gagamin hi’aa sasawar ana yomanin, Jesu misir naatu fanan aumetawat na’in eo, “Yait ta sikan namamamah, kwanihamiy nan ayu biyau harew natom!
38 Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà mí gbọ́ gẹ́gẹ́ bí Ìwé Mímọ́ ti wí, láti inú rẹ̀ ni odò omi ìyè yóò ti máa sàn jáde wá.”
38 Yait ayu inabitutumu na’at kuna biyau harew kutom. Buk Atamaninamaim eo na’atube ‘Harew yawasin boro o wanawananamaim nanunuw.’”
39 Ṣùgbọ́n ó sọ èyí ní ti ẹ̀mí, tí àwọn tí ó gbà á gbọ́ ń bọ̀ wá gbà, nítorí a kò tí ì fi Èmí Mímọ́ fún ni; nítorí tí a kò tí ì ṣe Jesu lógo.
39 Iti tur i sabuw iyab Jesu hinibitumitum Anun Kakafiyin hinabaib i isah eo. Iti boun ana veya Anun Kakafiyin i men yait itin bai, anayabin Jesu i men Tamah ana aiwob itinimih.
40 Nítorí náà, nígbà tí ọ̀pọ̀ nínú ìjọ ènìyàn gbọ́ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, wọ́n wí pé, “Lóòótọ́ èyí ni wòlíì náà.”
40 Rou’ay wanawanan hima tur hinonowar sabuw afa hi’o, “Anababatun iti orot i God ana dinab orot.”
41 Àwọn mìíràn wí pé, “Èyí ni Kristi náà.”
41 Afa hi’o, “Iti orot i Rourubinen.” Naatu sabuw afa ibanak hi’o, “Rourubinen ana orot i boro men Galilee’ine nan?
42 Ìwé mímọ́ kò ha wí pé, Kristi yóò ti inú irú-ọmọ Dafidi wá, àti Bẹtilẹhẹmu, ìlú tí Dafidi ti wá?”
42 Buk Atamaninamaim eo Rourubinen i boro aiwob orot David ana rara’ane naatu boro Bethlehem David ana bar meraramaim.”
43 Bẹ́ẹ̀ ni ìyapa wà láàrín ìjọ ènìyàn nítorí rẹ̀.
43 Imih nati kou’ay wanawanan kouseb matar anayabin Jesu isan.
44 Àwọn mìíràn nínú wọn sì fẹ́ láti mú un; ṣùgbọ́n kò sí ẹnìkan tí ó gbé ọwọ́ lé e.
44 Sabuw afa hikok hitab hitafatum, baise men yait ta biyan butubun.
45 Ní ìparí, àwọn ẹ̀ṣọ́ tẹmpili padà tọ àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi lọ, wọ́n sì wí fún wọn pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin kò fi mú un wá?”
45 Imaibo Tafaror bar ma’utenayah himatabir hin firis ukwarih naatu Pharisee biyah hitit naatu firis ukwarih himisir ma’utenayah hibatiyih, “Aisimamih men kwa bai kwana kwatit?”
46 Àwọn ẹ̀ṣọ́ dáhùn wí pé, “Kò sí ẹni tí ó tí ì sọ̀rọ̀ bí ọkùnrin yìí rí!”
46 Ma’utenayah hiya’afutih hi’o, “Iti orot tur eo’o, i men orot afa te’eo na’atube eomih!”
47 Nítorí náà àwọn Farisi dá wọn lóhùn pé, “A ha tan ẹ̀yin jẹ pẹ̀lú bí?
47 Pharisee hibatiyih, “Kwa kwa’o anananiyan kwa auman ifuwi ebobonawiyi kakaf i?”
48 Ǹjẹ́ nínú àwọn ìjòyè, tàbí àwọn Farisi ti gbà á gbọ́ bí?
48 “Kwata’itin ukwarih afa o Pharisee orot afa tur hinonowaraban Jesu hitumitum?
49 Ṣùgbọ́n ìjọ ènìyàn yìí, tí ko mọ òfin di ẹni ìfibú.”
49 Aiyabin! Iti rou’ay Moses ana ofafar i men ta hiso’ob, imih i God ana orarafen baban tema’am!”
50 Nikodemu ẹni tí ó tọ Jesu wá lóru rí, tí ó sì jẹ́ ọ̀kan nínú wọn sì sọ fún wọn pé,
50 I taiyuwih hai orot ta wabin Nicodemus i wan in Jesu biyan tit,
51 “Òfin wa ha ń ṣe ìdájọ́ ènìyàn kí ó tó gbọ́ ti ẹnu rẹ̀ àti kí ó tó mọ ohun tí ó ṣe bí?”
51 Imih i ana kou’ay ibatiyih, “It ata ofafar eo orot anasinaf kakaf i wan tananuwet imaibo tanab tanan ata ofafaramaim tanibabatiy.”
52 Wọ́n dáhùn wọ́n sì wí fún un pé, “Ìwọ pẹ̀lú wá láti Galili bí? Wá kiri, kí o sì wò nítorí kò sí wòlíì kan tí ó ti Galili dìde.”
52 Hiya’afut hi’o, “Nicodemus o auman i Galilee orot? Baise Buk Atamaninamaim inanunuwet boro men inatita’ur, dinab orot i men Galilee’ine na.”
53 Wọ́n sì lọ olúkúlùkù sí ilé rẹ̀.
53 (Naatu rou’ay hima’am hitarboubun himisir hai bar hai bar hin.)
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar João 7, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.