João 6
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, Jesu kọjá sí apá kejì Òkun Galili, tí í ṣe Òkun Tiberia.
1 Nati ufunamaim ana veya ta, Jesu Galilee harew isobon rabon rewan rounane (wabin ta Taibirias kukuf.)
2 Ọ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn sì tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, nítorí tí wọ́n rí iṣẹ́ àmì rẹ̀ tí ó ń ṣe lára àwọn aláìsàn.
2 Naatu sabuw rou’ay gagamin maiyow hi’ufunun hin anayabin sabuw sawusawuwih biyahimaim ina’inan sinaf biyawasih hi’itan isan.
3 Jesu sì gun orí òkè lọ, níbẹ̀ ni ó sì gbé jókòó pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
3 Naatu Jesu yen in oyaw sisibinamaim tit naatu ana bai’ufununayah hina biyanamaim himarir hima.
4 Àjọ ìrékọjá ọdún àwọn Júù sì súnmọ́ etílé.
4 Jew sabuw hai Tar Nowaten hiyuw ana veya i na biyubin.
5 Ǹjẹ́ bí Jesu ti gbé ojú rẹ̀ sókè, tí ó sì rí ọ̀pọ̀ ènìyàn wá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó wí fún Filipi pé, “Níbo ni a ó ti ra àkàrà, kí àwọn wọ̀nyí lè jẹ?”
5 Jesu nuw ra’at sabuw rou’ay gagamin maiyow isan hinan itih, naatu Philip ibatiy, “Rafiy menamaim boro tanatobon iti sabuw tanituwih?”
6 Ó sì sọ èyí láti dán an wò; nítorí tí òun fúnra rẹ̀ mọ ohun tí òun ó ṣe.
6 Iti i Philip fufunin isan ibibatiy, anayabin i ana notamaim so’obaka i boro abistan nasinaf.
7 Filipi dá a lóhùn pé, “Àkàrà igba owó idẹ kò lè tó fún wọn, bí olúkúlùkù wọn kò tilẹ̀ ní í rí ju díẹ̀ bù jẹ.”
7 Philip iya’afut eo, “Orot ana baiyan sumar eight ana fofonin tatab rafiy tatutubun sabuw ta’ita’imon tatabituwih i kikimin kwanekwan.”
8 Ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Anderu, arákùnrin Simoni Peteru wí fún un pé,
8 Imaibo ana bai’ufununayah orot ta, Andrew, Simon Peter tain awan tara’ah eo,
9 “Ọmọdékùnrin kan ń bẹ níhìn-ín yìí, tí ó ní ìṣù àkàrà barle márùn-ún àti ẹja wẹ́wẹ́ méjì, ṣùgbọ́n kín ni ìwọ̀nyí jẹ́ láàrín ọ̀pọ̀ ènìyàn wọ̀nyí?”
9 “Kek ta iti’imaim rafiy afu’afusar umat roun naatu siy rou’ab umanamaim hima’am aitin. Baise anotanot boro men nakaram, sabuw i ra’at kwanekwan.”
10 Jesu sì wí pé, “Ẹ mú kí àwọn ènìyàn náà jókòó!” Koríko púpọ̀ sì wá níbẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọkùnrin náà jókòó; ìwọ̀n ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn ní iye.
10 Nati’imaim samar gewasin tuw inu’in, imih Jesu eo, “Sabuw kwa’uwih samar yan timarir. naatu sabuw samar yan himarir hima, naatu oro’orotowat hibiyab etei 5,000.
11 Jesu sì mú ìṣù àkàrà náà. Nígbà tí ó sì ti dúpẹ́, ó pín wọn fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì pín wọn fún àwọn tí ó jókòó; bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ sì ni ẹja ní ìwọ̀n bí wọ́n ti ń fẹ́.
11 Jesu faraw bai, God ana merar yi, naatu sabuw himarir hima’am faramih, siy bai ef ta’imon sinaf, etei hi’aa yah gadid hai fofonin bai.
12 Nígbà tí wọ́n sì yó, ó wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ kó àjẹkù tí ó kù jọ, kí ohunkóhun má ṣe ṣòfò.”
12 Naatu hai fofonin baib ufunamaim, Jesu ana bai’ufununayah iuwih eo, “Hi’aa tuturih etei kwaita’ay, men ta kwanihamiy.”
13 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n kó wọn jọ wọ́n sì fi àjẹkù ìṣù àkàrà barle márùn-ún náà kún agbọ̀n méjìlá, èyí tí àwọn tí ó jẹun jẹ kù.
13 Basit hi’aa tuturih hi’o’on naatu kaifet hibiwanen etei 12, iti i rafiy fafar umat roun naatu siy rou’abamaim sabuw bituwih.
14 Nítorí náà nígbà tí àwọn ọkùnrin náà rí iṣẹ́ àmì tí Jesu ṣe, wọ́n wí pé, “Lóòótọ́ èyí ni wòlíì náà tí ń bọ̀ wá sí ayé.”
14 Iti ina’inan Jesu sinaf sabuw hi’i’itin ufunamaim hibusuruf hi’o, “Turobe iti orot i dinabamon, i namih hi’o’oban na tafaramamaim tit.”
15 Nígbà tí Jesu sì wòye pé wọ́n ń fẹ́ wá fi agbára mú òun láti lọ fi jẹ ọba, ó tún padà lọ sórí òkè, òun nìkan.
15 Jesu itih so’ob boro kafa’imo hinan hinab naatu hinau’kikin ni’aiwob, imih i hamenamo nati efan ihamiy naatu akisinamo yen in oyaw wan.
16 Nígbà tí alẹ́ sì lẹ́, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ sí Òkun.
16 Veya re birabirab ana bai’ufununayah hire hin harew kukuf hitit,
17 Wọ́n sì bọ́ sínú ọkọ̀ ojú omi, wọ́n sì rékọjá Òkun lọ sí Kapernaumu. Ilẹ̀ sì ti ṣú, Jesu kò sì tí ì dé ọ̀dọ̀ wọn.
17 Jesu isan hima hikakaif mar bu’u’um, men na biyah tit, imih wa hibai hiboy hirabon au Capernaum.
18 Òkun sì ń ru nítorí ẹ̀fúùfù líle tí ń fẹ́.
18 Nati ana veya kotar bitufuwan wanawanan hin naatu yabat busuruf ra’at.
19 Nígbà tí wọ́n wa ọkọ̀ ojú omi tó bí ìwọ̀n ibùsọ̀ mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n tàbí ọgbọ̀n, wọ́n rí Jesu ń rìn lórí Òkun, ó sì súnmọ́ ọkọ̀ ojú omi náà; ẹ̀rù sì bà wọ́n.
19 Hiboy hitit hire hikuyowen five o six kilometres na’atube hinuwanuw Jesu nahine riy yan bat remor wa isan nan hi’itin yah birubir fafar.
20 Ṣùgbọ́n ó wí fún wọn pé, “Èmi ni; ẹ má bẹ̀rù.”
20 Baise isah eaf eo, “Ayu o! men kwanabirumih!”
21 Nítorí náà wọ́n fi ayọ̀ gbà á sínú ọkọ̀; lójúkan náà ọkọ̀ náà sì dé ilẹ̀ ibi tí wọ́n ń lọ.
21 Imaibo ereyasisir hiu na wa afe’en yen, naatu men yok efan hinot hinanamaim awar hiyut.
22 Ní ọjọ́ kejì nígbà tí àwọn ènìyàn tí ó dúró ní òdìkejì Òkun rí i pé, kò sí ọkọ̀ ojú omi mìíràn níbẹ̀, bí kò ṣe ọ̀kan náà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wọ̀, àti pé Jesu kò bá àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wọ inú ọkọ̀ ojú omi náà, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ nìkan ni ó lọ.
22 Marto, sabuw rou’ay nati harew kukuf rounane hima hinunuwabon wa ta’imon nati’imaim batabat hi’inan, naatu hiso’ob Jesu i men nati wa’amaim isra’at bairi hinamih, baise ana bai’ufununayah akisihimo hinan hi’itih.
23 Ṣùgbọ́n àwọn ọkọ̀ ojú omi mìíràn ti Tiberia wá, létí ibi tí wọn gbé jẹ àkàrà, lẹ́yìn ìgbà tí Olúwa ti dúpẹ́.
23 Imaibo wa afa Taibiriasine hina efan nati Regah faraw bai igegewasin sabuw bituwih sisibinamaim hirun.
24 Nítorí náà nígbà tí àwọn ènìyàn rí i pé Jesu tàbí ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kò sí níbẹ̀, àwọn pẹ̀lú wọ ọkọ̀ ojú omi lọ sí Kapernaumu, wọ́n ń wá Jesu.
24 Naatu sabuw wa afe’en hinunuwatet Jesu ana bai’ufununayah bairi men hi’it fa’arih, matah kabiy wa hibow au Capernaum na’at Jesu hinuwih hin.
25 Nígbà tí wọ́n sì rí i ní apá kejì Òkun, wọ́n wí fún un pé, “Rabbi, nígbà wo ni ìwọ wá síyìn-ín yìí?”
25 Jesu harew kukuf rewan rounane ma’am hitita’ur, naatu hibatiy, “Bai’obaiyenayan, biyika ina itit kuma’am?”
26 Jesu dá wọn lóhùn ó sì wí pé, “Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo wí fún yín. Ẹ̀yin ń wá mi, kì í ṣe nítorí tí ẹ̀yin rí iṣẹ́ àmì, ṣùgbọ́n nítorí ẹ̀yin jẹ àjẹyó ìṣù àkàrà.
26 Jesu iyafutih eo, “Anababatun a tur ao’owen, ayu kwanunuwuhu i men ina’inan asisinaf kwa’i’itin isan, baise kwa rafiy kwa’aan ya gagadid isan ayu kwanuwuhu kwanan.
27 Ẹ má ṣe ṣiṣẹ́ fún oúnjẹ tí ń ṣègbé, ṣùgbọ́n fún oúnjẹ tí ó wà títí di ayé àìnípẹ̀kun, èyí tí Ọmọ Ènìyàn yóò fi fún yín. Nítorí pé òun ni, àní Ọlọ́run Baba ti fi èdìdì dì í.”
27 Bay nati eafe’af isan men kwanabowamih, baise ma’ama wanatowan ana bay isan i raro nanababan, nati bay i Orot Natun boro kwa nit. Anayabin God ayu Tamai ana baibasit nati bay roufaramin isan ana fair ayu itu.”
28 Nígbà náà ni wọ́n wí fún wọn pé, “Kín ni àwa ó ha ṣe, kí a lè ṣe iṣẹ́ Ọlọ́run?”
28 Imaibo Jesu hibatiy, “Bo aki boro mi’itube anasinaf saise God abistan eo imaim anasinaf?”
29 Jesu dáhùn, ó sì wí fún wọn pé, “Èyí ni iṣẹ́ Ọlọ́run pé, kí ẹ̀yin gba ẹni tí ó rán an gbọ́.”
29 Jesu iyafutih eo, “God ana bowabow bow isan i iti. Orot yait God biyafar i kwanitumitum.
30 Nígbà náà ni wọ́n wí fún wọn pé, “Iṣẹ́ àmì kín ní ìwọ ń ṣe, tí àwa lè rí, kí a sì gbà ọ́ gbọ́? Iṣẹ́ kín ní ìwọ ṣe?
30 Imih i hibatiy, “Ina’inan fairin menatan boro inasinaf aki ana’itin naatu o anitutumi? O boro abistan inasinaf?
31 Àwọn baba wa jẹ manna ní aginjù; gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, ‘Ó fi oúnjẹ láti ọ̀run wá fún wọn jẹ.’ ”
31 It ata a’agir arar yanamaim i rafiy wabin manna hi’aa; Buk Atamaninamaim hikirum hi’o’o na’atube, I mar ana rafiy itih hi’aa.”
32 Nígbà náà ni Jesu wí fún wọn pé, “Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo wí fún yín, kì í ṣe Mose ni ó fi oúnjẹ fún yín láti ọ̀run wá, ṣùgbọ́n Baba mi ni ó fi oúnjẹ òtítọ́ náà fún yín láti ọ̀run wá.
32 Naatu Jesu hai tur eowen eo, “Anababatun a tur ao’owen, “Iti mar ana rafiy kwa kwa’ani’aan i men Moses kwa itimih, baise ayu Tamai rafiy anababatun marane kwa it.
33 Nítorí pé oúnjẹ Ọlọ́run ni èyí tí ó ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá, tí ó sì fi ìyè fún aráyé.”
33 Anayabin God ana rafiy i orot yait marane rara’iy sabuw etei tafaram wanawanan yawas ebitih.”
34 Nígbà náà ni wọ́n wí fún un pé, “Olúwa, máa fún wa ní oúnjẹ yìí títí láé.”
34 Sabuw hi’o, “Regah iti rafiy i mar etei initi ana’aan.”
35 Jesu wí fún wọn pé, “Èmi ni oúnjẹ ìyè, ẹnikẹ́ni tí ó bá tọ̀ mí wá, ebi kì yóò pa á; ẹni tí ó bá sì gbà mí gbọ́, òǹgbẹ kì yóò gbẹ ẹ́ mọ́ láé.
35 Imaibo Jesu iuwih eo, “Ayu i yawas ana rafiy. Orot Yait ayu isou enan i boro men kafa’imo bayumih namorob, naatu orot yait ayu isou ebitumatum boro men kafa’imo sikan namamahimih.”
36 Ṣùgbọ́n mo wí fún yín pé, Ẹ̀yin ti rí mi, ẹ kò sì gbàgbọ́.
36 Naatu iti tur i ao kwanowaraka naatu mata yan kwa’i’itin baise men kafa’imo kwabitutumu.
37 Gbogbo èyí tí Baba fi fún mi, yóò tọ̀ mí wá; ẹni tí ó bá sì tọ̀ mí wá, èmi kì yóò tà á nù, bí ó tí wù kó rí.
37 Sabuw iyabowat ayu Tamai bitu boro ayu isou hinan, naatu orot babin yait ayu isou enan boro men ananun ufun natitamih.
38 Nítorí èmi sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run wá, kì í ṣe láti máa ṣe ìfẹ́ ti èmi fúnra mi, bí kò ṣe ìfẹ́ ti ẹni tí ó rán mi.
38 Anayabin ayu marane arara’iy, i men ayu au kok sinaf isanamih, baise orot yait ayu iyunu anan i ana kok anasinaf.
39 Èyí sì ni ìfẹ́ Baba tí ó rán mi pé ohun gbogbo tí o fi fún mi, kí èmi má ṣe sọ ọ̀kan nù nínú wọn, ṣùgbọ́n kí èmi lè jí wọn dìde níkẹyìn ọjọ́.
39 Naatu orot yait ayu iyunu anan ana kok i iti, sabuw iyabowat ayu bitu etei men ta anikasiy, baise mar yomaninamaim etei’imak anabuwih hinamisir.
40 Èyí sì ni ìfẹ́ ẹni tí ó rán mi, pé ẹnikẹ́ni tí ó bá wo ọmọ, tí ó bá sì gbà á gbọ́, kí ó lè ní ìyè àìnípẹ̀kun, Èmi ó sì jí i dìde níkẹyìn ọjọ́.”
40 Anayabin ayu Tamai ana kok i sabuw iyab matah etei Natun akisin ti’i’itin naatu tibitumitum boro ma’ama wanatowan ana yawas hinab; naatu mar yomaninamaim ayu boro anabuwih hinamisir.
41 Nígbà náà ni àwọn Júù ń kùn sí i, nítorí tí ó wí pé, “Èmi ni oúnjẹ tí ó ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá.”
41 Imaibo Jew sabuw hibusuruf Jesu isan higam, anayabin i eo, “Ayu i mar ana rafiy.
42 Wọ́n sì wí pé, “Jesu ha kọ́ èyí, ọmọ Josẹfu, baba àti ìyá ẹni tí àwa mọ̀? Báwo ni ó ṣe wí pé, ‘Èmi ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá’?”
42 Basit sabuw hi’o, “Iti orot i Jesu, Joseph natun, hinah tamah i taso’ob. Naatu baise boun i eo’o, Ayu i marane ara’iy.”
43 Nítorí náà Jesu dáhùn, ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ má ṣe kùn láàrín yín!
43 Jesu iyafutih eo, “Taiyuw men kwanagam.
44 Kò sí ẹnikẹ́ni tí ó lè wá sọ́dọ̀ mi, bí kò ṣe pé Baba tí ó rán mi fà á, Èmi ó sì jí i dìde níkẹyìn ọjọ́.
44 Sabuw boro men ayu isou hinan kwaneyan, baise Tamai ayu iyunu anan boro nabonawiyih hinan ayu biyau hinatit; naatu mar yomaninamaim ayu boro ana bora’ahih hinamisir.
45 A sá à ti kọ ọ́ nínú ìwé àwọn wòlíì pé, ‘A ó sì kọ́ gbogbo wọn láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá,’ nítorí náà ẹnikẹ́ni tí ó bá ti gbọ́, tí a sì ti ọ̀dọ̀ Baba kọ́, òun ni ó ń tọ̀ mí wá.
45 Dinab oro’orot hikirum hi’o na’atube, ‘Sabuw etei boro God ni’obaiyih. Orot yait Tamai fanan nowar naatu biyanane so’ob ebaib boro ayu isou nan.
46 Kì í ṣe pé ẹnìkan ti rí Baba bí kò ṣe ẹni tí ó ti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá, òun ni ó ti rí Baba.
46 Men yait ta Tamai itin; baise orot yait Godane nan i akisinamo Tamai itin.
47 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́, ó ní ìyè àìnípẹ̀kun.
47 Turobe a tur ao’owen, orot yait ebitumatum, yawas wanatowan i baika.
48 Èmi ni oúnjẹ ìyè.
48 Ayu i yawas ana rafiy.
49 Àwọn baba yín jẹ manna ní aginjù, wọ́n sì kú.
49 Kwa a’a’agir hai veya, rafiy wabin manna arar yanamaim hibow hi’aa, baise etei himorob.
50 Èyí ni oúnjẹ tí ó ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá, kí ènìyàn lè máa jẹ nínú rẹ̀ kí ó má sì kú.
50 Baise rafiy iti i marane ra’iy, sabuw iyab hinab hina’ani’aan boro men hina morob.
51 Èmi ni oúnjẹ ìyè náà tí ó ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá, bí ẹnikẹ́ni bá jẹ nínú oúnjẹ yìí, yóò yè títí láéláé, oúnjẹ náà tí èmi ó sì fi fún ni fún ìyè aráyé ni ara mi.”
51 Ayu i yawas ana rafiy, marane hiyafaru are. Orot babin yait iti rafiy na’ani’aan na’at boro nama wanatowan. Iti rafiy i ayu finimu boro anit, saise sabuw boro tafaramamaim yawas hinab hinama.”
52 Nítorí náà ni àwọn Júù ṣe ń bá ara wọn jiyàn, pé, “Ọkùnrin yìí yóò ti ṣe lè fi ara rẹ̀ fún wa láti jẹ?”
52 Naatu Jew sabuw iti tur hinonowar isan yah so’ar hibusuruf taiyuwih wanawanahimaim higam hikwaris hio, “Iti orot biyan finimin boro mi’itube nitit tana’animih eo?”
53 Nígbà náà ni Jesu wí fún wọn pé, “Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, bí kò ṣe pé ẹ̀yin bá jẹ ara Ọmọ Ènìyàn, kí ẹ sì mu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, ẹ̀yin kò ní ìyè nínú yin.
53 Jesu iuwih eo, “Turobe a tur ao’owen, Orot Natun biyan finimin men kwana’aan naatu ana rara men kwanatomatom, kwa wanawanamaim yawas men ema’am.
54 Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ ara mi, tí ó bá sì mu ẹ̀jẹ̀ mi, ó ní ìyè tí kò nípẹ̀kun. Èmi o sì jí i dìde níkẹyìn ọjọ́.
54 Orot yait ayu biyou finimin na’aan naatu au rara natomatom yawas wanatowan i bai, naatu yomaninamaim ayu boro ana bora’ah namisir.
55 Nítorí ara mi ni ohun jíjẹ nítòótọ́, àti ẹ̀jẹ̀ mi ni ohun mímu nítòótọ́.
55 Anayabin ayu biyou finimin i bay anababatun naatu au rara i harew anababatun,
56 Ẹni tí ó bá jẹ ara mi, tí ó bá sì mu ẹ̀jẹ̀ mi, ó ń gbé inú mi, èmi sì ń gbé inú rẹ̀.
56 orot babin yait ayu biyou finimin na’aan naatu au rara natomatom boro wanawana’umaim nama naatu ayu i wanawananamaim anama.
57 Gẹ́gẹ́ bí Baba alààyè ti rán mi, tí èmi sì yè nípa Baba gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó jẹ mí, òun pẹ̀lú yóò yè nípa mi.
57 Tamat yawas ana’an i ayu iyunu ana, anayabin i ema’am isan imih, ayu auman ama’am, ef ta’imonaban orot yait ayu biyau’umaim bai eani’aan boro yawasin nama anayabin ayu ama’am isan imih.
58 Èyí sì ni oúnjẹ náà tí ó sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run wá, kì í ṣe bí àwọn baba yín ti jẹ manna, tí wọ́n sì kú, ẹni tí ó bá jẹ́ oúnjẹ yìí yóò yè láéláé.”
58 Iti rafiy marane rara’iy i men kwa a a’agir manna hi’aa hibimumurub na’atube’emih, baise o yait iti rafiy boun marane rara’iy inab ina’ani’aan boro inama wanatowan.”
59 Nǹkan wọ̀nyí ni ó sọ nínú Sinagọgu, bí ó ti ń kọ́ni ní Kapernaumu.
59 Tur iti etei i Capernaum Kou’ay Bar wanawananamaim ma sabuw hai tur eowen i’obaibiyih.
60 Nítorí náà nígbà tí ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ gbọ́ èyí, wọ́n wí pé, “Ọ̀rọ̀ tí ó le ni èyí; ta ní lè gbọ́ ọ?”
60 Jesu ana bai’ufununayah moumurin na’in tur iti hinonowar hi’o, “Iti bai’obaiyen i fokarin. Yait boro iti tur nanowar nab?”
61 Nígbà tí Jesu sì mọ̀ nínú ara rẹ̀ pé àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń kùn sí ọ̀rọ̀ náà, ó wí fún wọn pé, “Èyí jẹ́ ìkọ̀sẹ̀ fún yín bí?
61 Baise Jesu ana bai’ufununayah abisa isan hio higamigam so’ob naatu iuwih eo, “Tur iti kwanonowar imaim kwa a naniyan ebi’afiy?
62 Ǹjẹ́, bí ẹ̀yin bá sì rí i tí Ọmọ Ènìyàn ń gòkè lọ sí ibi tí ó gbé ti wà rí ń kọ́?
62 Bo Orot Natun nayen ana efan marasika ma’am imaim nama kwana’itin boro mi’itube kwanao!
63 Ẹ̀mí ní ń sọ ni di ààyè; ara kò ní èrè kan; ọ̀rọ̀ wọ̀nyí tí mo sọ fún yín, ẹ̀mí ni, ìyè sì ni pẹ̀lú.
63 Anun Kakafiyin i yawas ebit biyat i aurin fair en. Iti tur kwa isa a’o i ayub ana tur naatu wanawananamaim i yawas ema’am.
64 Ṣùgbọ́n àwọn kan wà nínú yín tí kò gbàgbọ́.” Nítorí Jesu mọ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ wá ẹni tí wọ́n jẹ́ tí kò gbàgbọ́, àti ẹni tí yóò fi òun hàn.
64 Baise kwa afa iti kwama’am i men kwabitumatum. Anayabin iyab men hinabitumatum naatu orot yait baban na’o Jesu so’obaka.”
65 Ó sì wí pé, “Nítorí náà ni mo ṣe wí fún yín pé, kò sí ẹni tí ó lè tọ̀ mí wá, bí kò ṣe pé a fi fún un láti ọ̀dọ̀ Baba mi wá.”
65 Ibanak eo maiye, “Anayabin iti isan kwa au’uwi, orot babin boro men asir ayu isou nan kwaneyanamih, baise Tamai ana baibasitamaim boro niwa’an isah naham hinan ayu isou.”
66 Nítorí èyí ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ padà sẹ́yìn, wọn kò sì bá a rìn mọ́.
66 Nati ana veya’amaim ana bai’ufununayah moumurih na’in hihamiy naatu himatabitabir hina’ufut hin.
67 Nítorí náà Jesu wí fún àwọn méjìlá pé, “Ẹ̀yin pẹ̀lú ń fẹ́ lọ bí?”
67 Jesu ana bai’ufununayah nah 12 ibatiyih. “Kwa auman kwakokok kwanan?”
68 Nígbà náà ni Simoni Peteru dá a lóhùn pé, “Olúwa, ọ̀dọ̀ ta ni àwa ó lọ? Ìwọ ni ó ni ọ̀rọ̀ ìyè àìnípẹ̀kun.
68 Simon Peter iya’afut eo, “Regah yait isan boro anan? Yawas wanatowan ana tur o akisimo biya ema’am.
69 Àwa sì ti gbàgbọ́, a sì mọ̀ pé ìwọ ni Kristi náà, Ọmọ Ọlọ́run alààyè.”
69 Aki abitumatum naatu aso’ob o i Kakafiyin Ta’imon Godane ina.”
70 Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ̀yin méjìlá kọ́ ni mo yàn, ọ̀kan nínú yín kò ha sì ya èṣù?”
70 Imaibo Jesu iyafutih eo, “Kwa na 12, i ayu arubini, baise kwa wanawanamaim orot ta i demon mowan.”
71 (Ó ń sọ ti Judasi Iskariotu ọmọ Simoni ọ̀kan nínú àwọn méjìlá, nítorí pé òun ni ẹni tí yóò fi í hàn.)
71 (Jesu iti tur eo’o i Judas Simon Iscariot natun isan, Judas i bai’ufununayan nah 12 wanawanahimaim orot ta, yomaninamaim i boro Jesu nayanuw namorob.)
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar João 6, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.