João 5

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, àjọ àwọn Júù kan kò; Jesu sì gòkè lọ sí Jerusalẹmu.
1 Veya bai’ab sawar ufunamaim, Jew hai hiyuw aa isan Jesu yen in Jerusalem.
2 Adágún omi kan sì wà ní Jerusalẹmu, létí bodè àgùntàn, tí a ń pè ní Betisaida ní èdè Heberu, tí ó ní ẹnu-ọ̀nà márùn-ún.
2 Jerusalem wanawanan efan wabin For Hirahir sisibinamaim i harew kukuf, naatu ana seboseb etei umatroun hiwowaben Aramek fanahimaim tisusu’ub Betsaida,
3 Ní ẹ̀gbẹ́ odò yìí ni ọ̀pọ̀ àwọn abirùn ènìyàn máa ń gbé dùbúlẹ̀ sí, àwọn afọ́jú, arọ àti aláàrùn ẹ̀gbà.
3 nati sebosebomaim sabuw sawusawuwih moumurin maiyow hiya hi’inu’in, matah fim, ah umah kafikafirih, naatu ah umah ririmih hima hikakaif harew tabi’etaw isan.
4 — ausente —
4 Anayabin veya ta ta Regah ana tounamatar boro nara’iy harew kukuf nabenei niyabat rarouw nayen. Naatu sabuw sawow ana yumat ta ta hibow hina ti’inu’in, yait wan nara’iy nakifukif i boro nayawas.
5 Ọkùnrin kan wà níbẹ̀, ẹni tí ó tí wà ní àìlera fún ọdún méjìdínlógójì.
5 Orot ta sawow bai ma kwamur etei 38 i nati wanawanahimaim.
6 Bí Jesu ti rí i ní ìdùbúlẹ̀, tí ó sì mọ̀ pé ó pẹ́ tí ó ti wà bẹ́ẹ̀, ó wí fún un pé, “Ìwọ fẹ́ kí a mú ọ láradá bí?”
6 Jesu nuw orot nati’imaim inu’in itin, naatu so’ob orot sawow nati bai virurumin maiyow, imih orot ibatiy, “O kukokok inayawas?”
7 Abirùn náà dá a lóhùn wí pé, “Arákùnrin, èmi kò ní ẹni tí ìbá gbé mi sínú adágún, nígbà tí a bá ń rú omi náà, bí èmi bá ti ń bọ̀ wá, ẹlòmíràn a sọ̀kalẹ̀ sínú rẹ̀ síwájú mi.”
7 Orot iya’afut eo, “Regah, anamaramaim harew iyabat rarouw eyey, men yait ta boro nibaisu nabuwu anara’iy harew kukuf yan. Ayu misir ra’iyemih abiwa’an, sabuw afa i wan hira’iyeka.”
8 Jesu wí fún un pé, “Dìde, gbé àkéte rẹ, kí o sì máa rìn.”
8 Naatu Jesu orot isan eo, “Kumisir! A ir kunu naatu kuremor kwen.”
9 Lọ́gán, a sì mú ọkùnrin náà láradá, ó sì gbé àkéte rẹ̀, ó sì ń rìn.
9 Mar ta’imon orot yawas; misir ana ir nu bat remor.
10 Nítorí náà àwọn Júù wí fún ọkùnrin náà tí a mú láradá pé, “Ọjọ́ ìsinmi ni òní; kò tọ́ fún ọ láti gbé àkéte rẹ.”
10 Naatu Jew sabuw orot yayawas isan hi’o, “Iti boun i Baiyarir ana veya, ata ofafar men ebibasit o a ir ina’abar.”
11 Ó sì dá wọn lóhùn wí pé, “Ẹni tí ó mú mi láradá, ni ó wí fún mi pé, ‘Gbé àkéte rẹ, kí o sì máa rìn.’ ”
11 Baise iya’afutih eo, “Orot yait ayu biyawasu iuwu, ‘Kumisir a ir kunu naatu kubat kuremor.’”
12 Nígbà náà ni wọ́n bi í lérè wí pé, “Ọkùnrin wo ni ẹni tí ó wí fún ọ pé gbé àkéte rẹ, kí o sì máa rìn?”
12 Imih hibatiy, “Nati orot i yait uwi a ir inu i’abar ibat kureremor?”
13 Ẹni tí a mú láradá náà kò sì mọ̀ ẹni tí ó jẹ́ nítorí Jesu ti kúrò níbẹ̀, àwọn ènìyàn púpọ̀ wà níbẹ̀.
13 Orot nati yayawas i men kafa’imo so’ob orot i yait, anayabin sabuw moumurin maiyow nati’imaim hibatabat Jesu sorabon in kasiy.
14 Lẹ́yìn náà, Jesu rí i nínú tẹmpili ó sì wí fún un pé, “Wò ó, a mú ọ láradá: má ṣe dẹ́ṣẹ̀ mọ́, kí ohun tí ó burú ju èyí lọ má ba à bá ọ!”
14 Nati ufunamaim Jesu Tafaror Bar wanawanan tita’ur naatu iu, “Kwi’itin, o iyawas. Bowabow kakafih inihamiyen o sawar kakafin anababatun boro biyamaim namatar.”
15 Ọkùnrin náà lọ, ó sì sọ fún àwọn Júù pé, Jesu ni ẹni tí ó mú òun láradá.
15 Orot nati’imaim tit in, Jew sabuw hai tur eowen i Jesu iyawas.
16 Nítorí èyí ni àwọn Júù ṣe inúnibíni sí Jesu, wọ́n sì ń wá ọ̀nà láti pa á, nítorí tí o ń ṣe nǹkan wọ̀nyí ní ọjọ́ ìsinmi.
16 Imih hibusuruf Jesu isan turamaim hi’u hi’a’a’afiy, anayabin i Baiyarir ana veya sawar iti na’atube sinaf isan.
17 Ṣùgbọ́n Jesu dá wọn lóhùn pé, “Baba mi ń ṣiṣẹ́ títí di ìsinsin yìí, èmi náà sì ń ṣiṣẹ́.”
17 Jesu isah eo, “Ayu Tamai i mar etei ebowabow, imih ayu auman boro anabow.”
18 Nítorí èyí ni àwọn Júù túbọ̀ ń wá ọ̀nà láti pa á, kì í ṣe nítorí pé ó ba ọjọ́ ìsinmi jẹ́ nìkan ni, ṣùgbọ́n ó wí pẹ̀lú pé, Baba òun ni Ọlọ́run jẹ́, ó ń mú ara rẹ̀ bá Ọlọ́run dọ́gba.
18 Ana’an iti isan Jew hisinaftobon ef hinuwet Jesu asabunin isan; men Baiyarir ana ofafar ea’eastu’ub akisin, baise God isan Tamah rouw eo’omaim, iwa’an taiyuwin bai yen in God hairi anafofonin matar.
19 Nígbà náà ni Jesu dáhùn, ó sì wí fún wọn pé, “Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ọmọ kò lè ṣe ohunkóhun fún ara rẹ̀, bí kò ṣe ohun tí ó bá rí pé Baba ń ṣe, nítorí ohunkóhun tí baba bá ń ṣe, ìwọ̀nyí ni ọmọ náà sì ń ṣe pẹ̀lú.
19 Jesu iyafutih eo. “Turobe a tur ao’owen, Orot Natun akisin ana kok men karam nasinaf; baise Tamah abistan sinaf i i’itinimaim boro nasinaf, anayabin Tamah abistan isisinaf na’atube Natun isisinaf.
20 Nítorí Baba fẹ́ràn ọmọ, ó sì ti fi ohun gbogbo tí ó ń ṣe hàn án, òun yóò sì fi iṣẹ́ tí ó tóbi jù wọ̀nyí lọ hàn án, kí ẹnu lè yà yín.
20 Anayabin Tamah i Natun iyabuw sawar etei esisinaf na’atube Natun i’obaiy imaim esisinaf. Turobe, kwa a baifofofor isan, i boro sawar gagamihika ni’obaiy nasinaf men boun iti na’atube.
21 Nítorí pé, gẹ́gẹ́ bí Baba ti ń jí òkú dìde, tí ó sì ń sọ wọ́n di alààyè: bẹ́ẹ̀ ni ọmọ ń sọ àwọn tí ó fẹ́ di alààyè pẹ̀lú.
21 Tamah murumurubih imisiruwih yawas ebitih na’atube, nati ef ta’imon Natun ekok yait yawas baitinamih boro nitin.
22 Nítorí pé Baba kì í ṣe ìdájọ́ ẹnikẹ́ni, ṣùgbọ́n ó ti fi gbogbo ìdájọ́ lé ọmọ lọ́wọ́,
22 I na’atube Tamah men yait ta ebibatiy, baise baibabatiyen ana fair tutufin etei Natun itin.
23 kí gbogbo ènìyàn lè máa fi ọlá fún ọmọ gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ń fi ọlá fún Baba. Ẹnikẹ́ni tí kò bá fi ọlá fún ọmọ, kò fi ọlá fún Baba tí ó ran an.
23 Saise sabuw etei Tamah tirurusagiy na’atube, Natun boro hinarusagiy. Imih o yait Natun men kururusagiy, Tamah, i ana baiyonenayan auman men kururusagiy.
24 “Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ẹnikẹ́ni tí ó bá gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, tí ó bá sì gba ẹni tí ó rán mi gbọ́, ó ní ìyè tí kò nípẹ̀kun, òun kì yóò sì wá sí ìdájọ́; ṣùgbọ́n ó ti ré ikú kọjá bọ́ sí ìyè.
24 “Turobe a tur ao’owen, o yait ayu au tur inowar naatu menatan ayu iyafaru anan kubitumitum, o i yawas ma’ama wanatowan ibaika, naatu o boro men baibatebat inab, anayabin morobone irabon yawas wanawanan irun.
25 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, wákàtí náà ń bọ̀, ó sì dé tán nísinsin yìí, nígbà tí àwọn òkú yóò gbọ́ ohùn Ọmọ Ọlọ́run, àwọn tí ó bá gbọ́ yóò sì yè.
25 Turobe a tur ao’owen, veya i enan naatu i na titaka, nati ana veya murumurubih boro God Natun fanan hinanowar naatu iyab fanan hinanonowar boro yawas hinab hinama.
26 Nítorí pé gẹ́gẹ́ bí Baba ti ní ìyè nínú ara rẹ̀; gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ó sì fi fún ọmọ láti ní ìyè nínú ara rẹ̀;
26 Anayabin Tamah taiyuwin i yawas an, imih nati yawas ta’imon Natun itin yawas an matar.
27 Ó sì fún un ní àṣẹ láti máa ṣe ìdájọ́ pẹ̀lú, nítorí tí òun jẹ́ Ọmọ Ènìyàn.
27 Naatu i baibabatiyen ana fair Natun itin, anayabin i, i Orot Natun.
28 “Kí èyí má ṣe yà yín lẹ́nu; nítorí pé wákàtí ń bọ̀, nínú èyí tí gbogbo àwọn tí ó wà ní ibojì yóò gbọ́ ohun rẹ̀.
28 “Tur iti ao isan men kwana’ororsa’ir; veya i nati namamataramaim enan, murumurubih etei boro fanan hinanowar,
29 Wọn ó sì jáde wá; àwọn tí ó ṣe rere, sí àjíǹde ìyè; àwọn tí ó sì ṣe búburú sí àjíǹde ìdájọ́.
29 hai rahane hinatit, naatu iyab gewasin hisisinaf boro hinamisir yawas hinab, iyab kakafih hinasisinaf boro hinakusairih.”
30 Èmi kò le ṣe ohun kan fún ara mi, bí mo ti ń gbọ́ ni, mo ń dájọ́, òdodo sì ni ìdájọ́ mi; nítorí èmi kò wá ìfẹ́ ti èmi fúnra mi, bí kò ṣe ìfẹ́ ti ẹni tí ó rán mi.
30 “Ayu men karam akisu au kok ana sinaf, baise abisa God iu’uwu’umaim sabuw abibabatiyih, imih ayu au baibatiyen i mutufor, anayabin men ayu au kokomaim asisinaf, baise orot yait ayu iyunu anan i anakok asisinaf.
31 “Bí èmi bá ń jẹ́rìí ara mi, ẹ̀rí mi kì í ṣe òtítọ́.
31 Ayu taiyuwu au sinaf isan ana’o’orereb na’at, au tur i men turobe’emih.
32 Ẹlòmíràn ni ẹni tí ń jẹ́rìí mi; èmi sì mọ̀ pé, òtítọ́ ni ẹ̀rí mi tí ó jẹ́.
32 Baise orot ta ayu isou eo’orereb, i a tur ao’owen i ana orereb ayu isou i turobe.
33 “Ẹ̀yin ti ránṣẹ́ lọ sọ́dọ̀ Johanu, òun sì ti jẹ́rìí sí òtítọ́.
33 Kwaso’ob gewasomih kob abarayah John isan kwaiyafarih hinan John i turobe kwa a tur eowen.
34 Ṣùgbọ́n èmi kò gba ẹ̀rí lọ́dọ̀ ènìyàn, nǹkan wọ̀nyí ni èmi ń sọ, kí ẹ̀yin lè là.
34 Iti i men kwa orot maiyow isou kwataorereb, baise iti ao saise mi’itube kwa yawas kwatab isan.
35 Òun ni fìtílà tí ó ń jó, tí ó sì ń tànmọ́lẹ̀, ẹ̀yin sì fẹ́ fún sá à kan láti máa yọ̀ nínú ìmọ́lẹ̀ rẹ̀.
35 John i hinow na’atube to’ab marakaw kwa it, naatu mar kikimin kwa ana marakaw isan kwaiyasisir.
36 “Ṣùgbọ́n èmi ní ẹ̀rí tí ó pọ̀jù ti Johanu lọ. Nítorí iṣẹ́ tí Baba ti fi fún mi láti ṣe parí, iṣẹ́ náà pàápàá tí èmi ń ṣe náà ń jẹ́rìí mi pé, Baba ni ó rán mi.
36 Baise ayu au orererebayan orot i gagamin, men iti John eo’orereb na’atube. Ayu au orererebayan i abisa Tamai iyunu ana asisinaf i eo’orereb, naatu nati ebi’obaiyi ayu i Tamai iyafaru anasinaf isan, orot ta eo’orereb i John eo’orereb natabir, anayabin iti bowabow ayu Tamai bitu i anisawar, naatu iti bowabowamaim eo’orereb Ayu Tamai iyunu ana i ana bowabow anabow.
37 Àti Baba tìkára rẹ̀ tí ó rán mi ti jẹ́rìí mi. Ẹ̀yin kò gbọ́ ohùn rẹ̀ nígbà kan rí, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò rí ìrísí rẹ̀.
37 Naatu Tamai iyunu anan i taiyuwin ayu isou eo’orereb. Kwa men kafa’imo fanan kwanowar naatu yumatan kwa’itin.
38 Ẹ kò sì ní ọ̀rọ̀ rẹ̀ láti máa gbé inú yín, nítorí ẹni tí ó rán, òun ni ẹ̀yin kò gbàgbọ́.
38 Kwa ana tur men dogor wanawanan run, anayabin menatan ayu iyunu anan i men kwabitumitum.
39 Ẹ̀yin ń wá ìwé mímọ́ nítorí ẹ̀yin rò pé nínú wọn ni ẹ̀yin ní ìyè tí kò nípẹ̀kun. Wọ̀nyí sì ni àwọn tí ó ń jẹ́rìí mi.
39 Kwa Buk Atamaninamaim hikikirum kwaiyab kwabinotanot anayabin boro imaim yawas wanatowan kwanab. Nati tur i ayu isou eo,
40 Ẹ̀yin kò sì fẹ́ láti wá sọ́dọ̀ mi, kí ẹ̀yin ba à lè ní ìyè.
40 baise men kwakokok kwanan ayu biyau yawas kwanab.
41 “Èmi kò gba ògo lọ́dọ̀ ènìyàn.
41 “Ayu men orot babin bora’ara’ahu isan ao’omih.
42 Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ pé, ẹ̀yin fúnra yín kò ní ìfẹ́ Ọlọ́run nínú yín.
42 baise kwa orot babin a yawas ayu aso’ob, kwa a yabow God isan dogoromaim i men ema’am.
43 Èmi wá ní orúkọ Baba mi, ẹ̀yin kò sì gbà mí; bí ẹlòmíràn bá wá ní orúkọ ara rẹ̀, òun ni ẹ̀yin yóò gbà.
43 Ayu Tamai wabinamaim anan kwa men kwabuwu au merar kwayi, baise orot babin ta i taiyuwin wabinamaim nanan boro kwanab ana merar kwanay.
44 Ẹ̀yin ó ti ṣe lè gbàgbọ́, ẹ̀yin tí ń gba ògo lọ́dọ̀ ara yín tí kò wá ògo tí ó ti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run nìkan wá?
44 Kwa taiyuw baifa’i isan a kok gagamin, baise God ta’imonamo ana baifa’en i men kwakokok, imih ayu abisa ao boro kwanitutumu?
45 “Ẹ má ṣe rò pé, èmi ó fi yín sùn lọ́dọ̀ Baba, ẹni tí ń fi yín sùn wà, àní Mose, ẹni tí ẹ̀yin gbẹ́kẹ̀lé.
45 Men kwananot ayu boro Tamai nanamaim ubar kwa bait kwanarouw en, baise Moses kwa a not tutufin imaim kwayai kwama’am boro ubar nabit kwana’itin.
46 Nítorí pé ẹ̀yin ìbá gba Mose gbọ́, ẹ̀yin ìbá gbà mí gbọ́, nítorí ó kọ ìwé nípa tèmi.
46 Moses kwatabitumitum na’at, ayu boro kwatitutumu, anayabin i ayu isou kirum.
47 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá gba ìwé rẹ̀ gbọ́, ẹ̀yin ó ti ṣe gbà ọ̀rọ̀ mi gbọ́?”
47 Baise Moses abistan kikirum kwa men kwanabitumatum na’at, boro mi’itube ayu ao kwanitumatum?”

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar João 5, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.