João 3
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Ọkùnrin kan sì wà nínú àwọn Farisi, tí a ń pè ní Nikodemu, ìjòyè kan láàrín àwọn Júù.
1 Jew hai ukwarin orot wabin Nicodemus i Pharisee ana kou’ayamaim orot ta.
2 Òun náà ní ó tọ Jesu wá ní òru, ó sì wí fún un pé, Rabbi, àwa mọ̀ pé olùkọ́ni láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá ni ìwọ ń ṣe, nítorí pé kò sí ẹni tí ó lè ṣe iṣẹ́ àmì wọ̀nyí tí ìwọ ń ṣe, bí kò ṣe pé Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀.
2 Guguminamaim na Jesu biyan tit, naatu eo, “Bai’obaiyenayan, aki aso’ob o i bai’obaiyenayan God biyanane ina. Men yait ta karam boro ina’inanen fairih o kusisinafube nasinaf, God men hairi hinama’am na’at.” Jesus Nicodemus hairi bar tafan hima tibidudur|alt="Jesus and Nicodemus" src="CN01670b.tif" size="col" loc="Jhn 3.2" copy="©1978 David C. Cook Publishing Co." ref="3.1-4"
3 Jesu dáhùn ó sì wí fún un pé, “Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo wí fún ọ, bí kò ṣe pé a tún ènìyàn bí, òun kò lè rí ìjọba Ọlọ́run.”
3 Mar ta’imonamo Jesu iya’afut, “Ayu tur anababatun a tur ao’owen, men yait ta boro God ana ma’ama wanatowan na’itin, baise i boro natufuw maiye’ebo.”
4 Nikodemu wí fún un pé, a ó ti ṣe lè tún ènìyàn bí nígbà tí ó di àgbàlagbà tan? Ó ha lè wọ inú ìyá rẹ̀ lọ nígbà kejì, kí a sì bí i?
4 “Orot ra’at gagamin na’in ema’am, boro mi’itube natufuw maiye?” Nicodemus ibat. “Men karam hinah yan wanawanan narun mar bairou’abin natufuw maiye!”
5 Jesu dáhùn wí pé, “Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo wí fún ọ, bí kò ṣe pé a fi omi àti Ẹ̀mí bí ènìyàn, òun kò lè wọ ìjọba Ọlọ́run.
5 Jesu iya’afut eo, “Turobe a tur ao’owen, men yait ta boro God ana ma’ama wanatowan narun, baise i harew naatu Anuninamaim natufuw.
6 Èyí tí a bí nípa ti ara, ti ara ni; èyí tí a sì bí nípa ti Ẹ̀mí, ti Ẹ̀mí ni.
6 Biyat etatoub, i biyat eya’iy, baise Anun Kakafiyin etatoub Anun Kakafiyin iya’iy.
7 Kí ẹnu kí ó má ṣe yà ọ́, nítorí mo wí fún ọ pé, ‘A kò lè ṣe aláìtún yín bí.’
7 O boro men ita’ororsa’ir ayu tur iti tufuw maiye ao isan.
8 Afẹ́fẹ́ ń fẹ́ sí ibi tí ó gbé wù ú, ìwọ sì ń gbọ́ ìró rẹ̀, ṣùgbọ́n ìwọ kò mọ ibi tí ó gbé ti wá, àti ibi tí ó gbé ń lọ, gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni olúkúlùkù ẹni tí a bí nípa ti Ẹ̀mí.”
8 Waruw ana kokomaim ebababin. O i nidun kunonowar, baise o men karam boro inao, i menane na enan, o au mena’at babin enan. Imih orot babin anunihine i nati na’atube tetutufuw.”
9 Nikodemu dáhùn, ó sì wí fún un pé, “Nǹkan wọ̀nyí yóò ti ṣe lè rí bẹ́ẹ̀?”
9 Nicodemus i bat, “Iti i mi’itube?”
10 Jesu dáhùn, ó sì wí fún un pé, “Ṣé olùkọ́ni ní Israẹli ni ìwọ ń ṣe, o kò sì mọ nǹkan wọ̀nyí?
10 Jesu eo, “O i Israel hai bai’obaiyenayan naatu o iti sawar men imanamamih?”
11 Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo wí fún ọ, Àwa ń sọ èyí tí àwa mọ̀, a sì ń jẹ́rìí èyí tí àwa ti rí; ẹ̀yin kò sì gba ẹ̀rí wa.
11 Jesu iya’afut eo, “Ayu turobe a tur ao’owen, aki abisa asoso’ob i a’o, naatu abisa aki a’i’itin i isan a’o, baise kwa i boro’ika aki ai tur naniyan men kwabaibimih.
12 Bí mo bá sọ ohun ti ayé yìí fún yín, tí ẹ̀yin kò sì gbàgbọ́, ẹ̀yin ó ti ṣe gbàgbọ́ bí mo bá sọ ohun ti ọ̀run fún yín?
12 Ayu tafaram ana sawar isah ao kwanowar baise kwa men kwabitumatum. Kwa boro mi’itube kwanitumatum ayu mar ana sawar isah ana’o na’at?”
13 Kò sì ṣí ẹni tí ó gòkè re ọ̀run bí kò ṣe ẹni tí ó ti ọ̀run sọ̀kalẹ̀ wá, Ọmọ Ènìyàn tí ń bẹ ní ọ̀run.
13 Men yait ta in mar run, baise orot Natun marane nan akisinamo.
14 Bí Mose sì ti gbé ejò sókè ní aginjù, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni a kò le ṣe aláìgbé Ọmọ Ènìyàn sókè pẹ̀lú.
14 Moses mi’itube arar yan kok bora’ah na’atube, orot natun hinabora’ah nayen,
15 Kí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà á gbọ́, kí ó má bà á ṣègbé, ṣùgbọ́n kí ó le ní ìyè àìnípẹ̀kun.”
15 saise iyabowat i tebitumatum boro ma’ama wanatowan hinab.
16 “Nítorí Ọlọ́run fẹ́ aráyé tó bẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́, tí ó fi ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo fún ni, kí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà á gbọ́, má bà á ṣègbé, ṣùgbọ́n kí ó lè ní ìyè àìnípẹ̀kun.
16 God tafaram iyabuw kwanekwan imih i Natun ta’imonamo iyafar na, saise yait i ebitumitum boro men namorob, baise boro yawas wanatowan nab.
17 Nítorí Ọlọ́run kò rán ọmọ rẹ̀ sí ayé láti dá aráyé lẹ́jọ́; ṣùgbọ́n kí a le ti ipasẹ̀ rẹ̀ gba aráyé là.
17 God i men tafaram bai’afiyin isan Natun iyafar na tafaramaim titamih, baise tafaram baiyawasin isan na tit.
18 Ẹni tí ó bá gbà á gbọ́, a kò ní dá a lẹ́jọ́; ṣùgbọ́n a ti dá ẹni tí kò gbà á gbọ́ lẹ́jọ́ ná, nítorí tí kò gba orúkọ ọmọ kan ṣoṣo ti Ọlọ́run gbọ́.
18 O yait I kubitumitum boro men ina’afemih, baise o yait men ebitumitum i eaf sawar, anayabin i men God Natun Ta’imon, i akisinamo wabin itumitumamih.
19 Èyí ni ìdájọ́ náà pé, ìmọ́lẹ̀ wá sí ayé, àwọn ènìyàn sì fẹ́ òkùnkùn ju ìmọ́lẹ̀ lọ, nítorí tí iṣẹ́ wọn burú.
19 Iti i baib’afiyen. Marakaw na tafaramamaim tit, baise orot marakaw efanin gugumin iyabuw anayabin hai sinaf kakafih.
20 Nítorí olúkúlùkù ẹni tí ó bá hùwà búburú ní ìkórìíra ìmọ́lẹ̀, kì í sì í wá sí ìmọ́lẹ̀, kí a má ṣe bá iṣẹ́ rẹ̀ wí.
20 Orot babin etei sinaf kakafih tesisinaf i marakaw hikwahir naatu boro men hinan marakaw wanawanan hinarun, tebirubir hai sinaf boro hinirerereb.
21 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá ń sọ òtítọ́ ní í wá sí ìmọ́lẹ̀, kí iṣẹ́ rẹ̀ kí ó lè fi ara hàn pé a ṣe wọ́n nípa ti Ọlọ́run.”
21 Baise yait ta turobe’emaim ema’am marakaw wanatowan erur, saise i ana bowabow God wanawananamaim bowabow boro nirerereb.
22 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, Jesu pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wá sí ilẹ̀ Judea; ó sì dúró pẹ̀lú wọn níbẹ̀ ó sì ń ṣe ìtẹ̀bọmi fún ni.
22 Iti ufunamaim, Jesu ana bai’ufununayah bairi hitit hin Judea tafaram ufunane hirun, nati’imaim mar kikimin hima naatu bapataito itih.
23 Johanu pẹ̀lú sì ń ṣe ìtẹ̀bọmi ní Aenoni, ní agbègbè Salimu, nítorí tí omi púpọ̀ wà níbẹ̀, wọ́n sì ń wá, a sì ń tẹ̀ ẹ́ wọn bọ omi.
23 Nati’imaim John auman tafaram Aenonamaim sabuw bapataito bitih, Salim i men ef yok i sisibinamaim, anayabin nati’imaim i harew moumurih, naatu sabuw i nan ufun hinan bapataito bain isan.
24 (Nítorí tí a kò tí ì sọ Johanu sínú túbú).
24 (Iti John dibur hiyaru’uy ma’am nanamaim.)
25 Nígbà náà ni iyàn kan wà láàrín àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Johanu àti Júù kan nípa ti ìwẹ̀nù.
25 John ana bai’ufununayah afa naatu Jew sabuw afa wanawanahimaim gamin matar, bapataito ana ofafaren isan.
26 Wọ́n sì tọ Johanu wá, wọ́n sì wí fún un pé, “Rabbi, ẹni tí ó ti wà pẹ̀lú rẹ lókè odò Jordani, tí ìwọ ti jẹ́rìí rẹ̀, wò ó, òun tẹ àwọn ènìyàn bọ omi, gbogbo ènìyàn sì ń tọ̀ ọ́ wá.”
26 I hina John biyan hitit naatu hi’o, “Bai’obaiyenayan, orot nati o airi no Jordan harew rounane menatan isan o i’o’orerereb, i boun bapataito sabuw ebitih, naatu sabuw etei i isan tenan.”
27 Johanu dáhùn ó sì wí pé, “Ènìyàn kò le rí nǹkan kan gbà, bí kò ṣe pé a bá ti fi fún ún láti ọ̀run wá.
27 Nati isan John iya’afut eo, “Orot abistanawat marane tebitin iwat nab.
28 Ẹ̀yin fúnra yín jẹ́rìí mi pé mo wí pé, ‘Èmi kì í ṣe Kristi náà, ṣùgbọ́n pé a rán mi síwájú rẹ̀.’
28 Kwa taiyuw i karam ayu ao i kwanao’rereb, Ayu i men Keriso, baise ayu i nanamaim hiyafaru ana.
29 Ẹni tí ó bá ni ìyàwó ni ọkọ ìyàwó; ṣùgbọ́n ọ̀rẹ́ ọkọ ìyàwó tí ó dúró tí ó sì ń gbóhùn rẹ̀, ó ń yọ̀ gidigidi nítorí ohùn ọkọ ìyàwó; nítorí náà ayọ̀ mi yí di kíkún.
29 Babin orot ana rum hi’o ema’am, orot ana of menatan i bai’awaninamih i orot isan ma tainin rub ma ekakaif, naatu i ana rum fanan enonowar ana veya i anababatun ekakawasa. Iti kawasa i ayu nowau, naatu kawasa i boun ana yomanin a’asa’ub.
30 Òun kò lè ṣàì máa pọ̀ sí i, ṣùgbọ́n èmi kò lè ṣàìmá rẹlẹ̀.
30 I ana fair ra’at natabiru, ayu fair i men ra’at.”
31 “Ẹni tí ó ti òkè wá ju gbogbo ènìyàn lọ; ẹni tí ó ti ayé wá ti ayé ni, a sì máa sọ ohun ti ayé. Ẹni tí ó ti ọ̀run wá ju gbogbo ènìyàn lọ.
31 Yeit auyomane nan i ra’at etei natabirih, menatan iti tafaramane nan i tafaram nowan, naatu tafaram ana sawar isah i ebidudur. Menatan marane nan i sawar etei tafahimaim.
32 Ohun tí ó ti rí tí ó sì ti gbọ́ èyí náà sì ni òun ń jẹ́rìí rẹ̀; kò sì sí ẹni tí ó gba ẹ̀rí rẹ̀.
32 I abis nonowar, i’itanen i isah eo’orerereb, baise men yait ta ana tur ebaibimih.
33 Ẹni tí ó gba ẹ̀rí rẹ̀ fi èdìdì dì í pé, olóòtítọ́ ni Ọlọ́run.
33 Orot yait ta i ana tur nabitumitum na’at, i ebi’obaiyit i ebitumatum God abistan eo’o i turobe.
34 Nítorí ẹni tí Ọlọ́run ti rán ń sọ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: nítorí tí Ọlọ́run fi Ẹ̀mí fún un láìsí gbèdéke.
34 Menatan God biyafar i God ana tur eo’orerereb; anayabin God i Anun i nowanamih itin anababatun
35 Baba fẹ́ Ọmọ, ó sì ti fi ohun gbogbo lé e lọ́wọ́.
35 Tamah Natun iyabuw kwanekwan naatu sawar etei i ana fair babanamaim ya.
36 Ẹni tí ó bá gba Ọmọ gbọ́, ó ní ìyè àìnípẹ̀kun, ẹni tí kò bá sì gba Ọmọ gbọ́, kì yóò rí ìyè, nítorí ìbínú Ọlọ́run ń bẹ lórí rẹ̀.”
36 Yait ana baitumatum Natunamaim naya’iy boro yawas wanatowan nab, baise yait ta God Natun nabifutuw boro men yawas nitinimih, God ana yaso’ar tafahimaim nama.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar João 3, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.