João 1

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Ní àtètèkọ́ṣe ni Ọ̀rọ̀ wà, Ọ̀rọ̀ sì wà pẹ̀lú Ọlọ́run, Ọlọ́run sì ni Ọ̀rọ̀ náà.
1 Tafaram matara’e ana veya Tur i wan ma, naatu Tur i God hairi hima, naatu Tur i God taiyuwin.
2 Òun ni ó sì wà pẹ̀lú Ọlọ́run ní àtètèkọ́ṣe.
2 Tur i God hairi wan hima’abo tafaram matar.
3 Nípasẹ̀ rẹ̀ ni a dá ohun gbogbo; lẹ́yìn rẹ̀ a kò sì dá ohun kan nínú ohun tí a ti dá.
3 Tur wanawananamaim God sawar etei’imak sinafen himatar; iti sawar himamatar i etei tur wanawananamaim himatar men ta asir matar kwaneyanamih.
4 Nínú rẹ̀ ni ìyè wà, ìyè yìí náà sì ni ìmọ́lẹ̀ aráyé,
4 Tur i yawas an anababatun, naatu iti yawas i sabuw isah marakaw bai na.
5 ìmọ́lẹ̀ náà sì ń mọ́lẹ̀ nínú òkùnkùn, òkùnkùn kò sì borí rẹ̀.
5 Iti marakaw guguminamaim kusisiar, naatu gugumin men karam boro marakaw na’asabun.
6 Ọkùnrin kan wà tí a rán láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá; orúkọ ẹni tí ń jẹ́ Johanu.
6 God ana kob abarayan wabin John iyafar na tit;
7 Òun ni a sì rán fún ẹ̀rí, kí ó lè ṣe ẹlẹ́rìí fún ìmọ́lẹ̀ náà, kí gbogbo ènìyàn kí ó lè gbàgbọ́ nípasẹ̀ rẹ̀.
7 marakaw isan sif ruboun eorereb sabuw hinowar, naatu sabuw iyab tur hinonowar hitumatum.
8 Òun fúnra rẹ̀ kì í ṣe ìmọ́lẹ̀ náà, ṣùgbọ́n a rán an wá láti ṣe ẹlẹ́rìí fún ìmọ́lẹ̀ náà.
8 I taiyuwin i men marakaw; i marakaw akisin ana sif narubonamih na.
9 Ìmọ́lẹ̀ òtítọ́ ń bẹ tí ń tan ìmọ́lẹ̀ fún olúkúlùkù ènìyàn tí ó wá sí ayé.
9 Iti marakaw i turobe, marakaw anababatun, tafaramaim na sabuw tafahimaim ekukusisiar.
10 Òun sì wà ní ayé, àti pé, nípasẹ̀ rẹ̀ ni a sì ti dá ayé, ṣùgbọ́n ayé kò sì mọ̀ ọ́n.
10 Tur i na tafaram eo mamatar wanawananamaim ma, baise tafaram i men inanimih.
11 Ó tọ àwọn tirẹ̀ wá, àwọn tirẹ̀ kò sì gbà á.
11 I na ana tafaram tit, baise taiyuwin ana sabuw i men hibaimih.
12 Ṣùgbọ́n iye àwọn tí ó gbà á, àní àwọn náà tí ó gbà orúkọ rẹ̀ gbọ́, àwọn ni ó fi ẹ̀tọ́ fún láti di ọmọ Ọlọ́run.
12 Baise sabuw afa hibai naatu wabinamaim hitumitum, naatu baibasit itih i hina God natunatun himatar.
13 Àwọn ọmọ tí kì í ṣe nípa ẹ̀jẹ̀, tàbí nípa ti ìfẹ́ ara, bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe nípa ìfẹ́ ti ènìyàn, bí kò ṣe láti ọwọ́ Ọlọ́run.
13 God natunatun himamatar i men orot anarara, o men orot babin aawan hairi hi’in kek tetutufu na’atube’emih, baise i God akisin anakokok sinaf i natunatun himatar.
14 Ọ̀rọ̀ náà sì di ara, òun sì ń bá wa gbé. Àwa sì ti rí ògo rẹ̀, àní ògo ọmọ rẹ kan ṣoṣo, tí ó ti ọ̀dọ̀ Baba wá, ó kún fún oore-ọ̀fẹ́ àti òtítọ́.
14 Tur i na orot matar, naatu wanawanatamaim ma, ana marakaw bonamanamarin i taitin, iti marakaw bonamanamarin i God Natun ta’imonamo ebitin. Iti tur wanawanan i turobe naatu manaw kabeber awan karatan.
15 Johanu sì jẹ́rìí nípa rẹ̀, ó kígbe, ó sì wí pé, “Èyí ni ẹni tí mo sọ̀rọ̀ rẹ̀ pé, ‘Ẹni tí ń bọ̀ lẹ́yìn mi pọ̀jù mí lọ, nítorí òun ti wà ṣáájú mi.’ ”
15 John iti orot isan fanan sib binan eo,” Iti orot ayu isan ao’oban iti enan, anamaramaim ayu iti na’at ao, ‘I ayu ufu enan i ana fair ra’at ayu natabiru, anayabin i wan ma’abo ayu atufuw.’”
16 Nítorí láti inú ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ ni gbogbo wa sì ti gba ìbùkún kún ìbùkún.
16 I wanawanan manaw kabeber karsuwei it etei ebigegewasinit, ana baigegewasin tafan baban ebitit.
17 Nítorí pé nípasẹ̀ Mose ni a ti fi òfin fún ni ṣùgbọ́n òun; oore-ọ̀fẹ́ àti òtítọ́ láti ipasẹ̀ Jesu Kristi wá.
17 Anayabin God ana ofafar i Moses itin, baise manaw kabeber naatu turobe i Jesu Keriso’one na.
18 Kò sí ẹni tí ó rí Ọlọ́run rí, bí kò ṣe òun nìkan, àní ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo, ẹni tí òun pàápàá jẹ́ Ọlọ́run, tí ó sì wà ní ìbáṣepọ̀ tí ó súnmọ́ jùlọ pẹ̀lú baba, òun náà ni ó sì fi í hàn.
18 Men yait ta God itin. baise God Natun ta’imon Tamah wanawananamaim ema’am akisinamo God bai na bebeyanamaim tasusu’ub.
19 Èyí sì ni ẹ̀rí Johanu, nígbà tí àwọn Júù rán àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi láti Jerusalẹmu wá láti béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ ẹni tí òun ń ṣe.
19 Jew hai ukwarih Jerusalem hima’am firis afa naatu hai baibaisayah afa hiyafarih hin John hibatiy? “O i yait?”
20 Òun kò sì kùnà láti jẹ́wọ́, ṣùgbọ́n òun jẹ́wọ́ wọ́ọ́rọ́wọ́ pé, “Èmi kì í ṣe Kristi náà.”
20 I men baifuwenamaim iyafutih, baise i mutufor bebeyanamaim eorereb, “Ayu i men Keriso.”
21 Wọ́n sì bi í léèrè pé, “Ta ha ni ìwọ? Elijah ni ìwọ bí?”
21 Naatu hibatiy, “Bo o i yait? Om Elizah?” John eo, “Ayu men Elizah.” Ai o dinab orot?” John iya’afutih eo, “Ayu men dinab orot.”
22 Ní ìparí wọ́n wí fún un pé, “Ta ni ìwọ í ṣe? Fún wa ní ìdáhùn kí àwa kí ó lè mú èsì padà tọ àwọn tí ó rán wa wá lọ. Kí ni ìwọ wí nípa ti ara rẹ?”
22 Ibanak hibatiy maiye hio, “O i yait? Ku’o anowar saise anamatabir anan iyab hiyafari anan hai tur ana’owen. O taiyuw isa boro inakubuna ananowar.”
23 Johanu sì fi ọ̀rọ̀ wòlíì Isaiah fún wọn ní èsì pé, “Èmi ni ohùn ẹni tí ń kígbe ní ijù, ‘Ẹ ṣe ọ̀nà Olúwa ní títọ́.’ ”
23 John iya’afutih dinab orot Isaiah Buk Atamaninamaim kirum inu’in imaim eo, “Ayu i orot ta fanan araramaim eafa’af. Ef kwanarumutufur Regah ana remor isan!”
24 Ọ̀kan nínú àwọn Farisi tí a rán
24 Kob nayah Pharisee hiyafarih hina,
25 bi í léèrè pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ń bamitiisi nígbà náà, bí ìwọ kì í bá ṣe Kristi, tàbí Elijah, tàbí wòlíì náà?”
25 John hibatiy, “Bo o men Keriso, o Elizah o dinab orot na’at, aisim sabuw bapataito kubitih?”
26 Johanu dá wọn lóhùn, wí pé, “Èmi ń fi omi bamitiisi, ẹnìkan dúró láàrín yín, ẹni tí ẹ̀yin kò mọ̀,
26 John hai tur eowen eo, “Ayu harewamaim sabuw bapataito abitih, Baise kwa wanawanamaim orot ta ebatabat kwa men kwaso’ob.
27 Òun náà ni ẹni tí ń bọ̀ lẹ́yìn mi, okùn bàtà ẹni tí èmi kò tó láti tú.”
27 I Ayu ufu’umaim enan, an ana baibaiyon murab men gewasu boro anarufamen.”
28 Àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ó ṣẹlẹ̀ ní Betani ní òdìkejì odò Jordani, níbi tí Johanu ti ń fi omi bamitiisi.
28 Iti sawar etei i Bethany himatar harew Jordan sisibin veya yeninane, John sabuw bapataito bitihimaim.
29 Ní ọjọ́ kejì, Johanu rí Jesu tí ó ń bọ̀ wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó sì wí pé, “Wò ó, Ọ̀dọ́-àgùntàn Ọlọ́run, ẹni tí ó kó ẹ̀ṣẹ̀ ayé lọ!
29 Mar to John nuw Jesu nan itin eo, “Kwanuw God Ana Lamb tafaram ana kakafin bosairenayan enan kwa’itin!”
30 Èyí ni ẹni tí mo ń sọ nígbà tí mo wí pé, ‘Ọkùnrin kan tí ń bọ̀ wá lẹ́yìn mi, tí ó pọ̀jù mí lọ, nítorí tí ó ti wà ṣáájú mi.’
30 Iti orot isan ao’orereb anamaramaim iti na’atube ao, ‘Orot ayu ufu’umaim enan i ana fair ra’at kwanekwan, anayabin i wan ma’abo ayu a tufuw.’
31 Èmi gan an kò sì mọ̀ ọ́n, ṣùgbọ́n ìdí tí mo fi wá ń fi omi ṣe ìtẹ̀bọmi ni kí a lè fi í hàn fún Israẹli.”
31 Ayu taiyuwu auman iti orot men asu’ub, baise anayabin nati isan ayu harewamaim sabuw bapataito abitih imaim Israel sabuw isah tirerereb hitaso’ob’.
32 Nígbà náà ni Johanu jẹ́rìí sí i pé, “Mo rí Ẹ̀mí sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run wá bí àdàbà, tí ó sì bà lé e.
32 Naatu John iti tur eorereb. “Ayu Anunin mamu imag na’atube marane ra’iy naatu i tafanamaim mamara’at aitin.
33 Èmi kì bá tí mọ̀ ọ́n, bí kò ṣe pé ẹni tí ó rán mi láti fi omi bamitiisi sọ fún mi pé, ‘Ọkùnrin tí ìwọ rí tí Ẹ̀mí sọ̀kalẹ̀ tí ó bà lé lórí ni ẹni tí yóò fi Ẹ̀mí Mímọ́ bamitiisi.’
33 Ayu iti orot i boro men ataso’ob, baise God iyunu ana harewamaim sabuw bapataito abitih i au tur eowen, ‘Orot yait Anunin nara’iy tafanamaim namara’at ina’i’itin, i boro Anun Kakafiyinamaim bapataito nitih.’”
34 Èmi ti rí i, mo sì jẹ́rìí pé, èyí ni Ọmọ Ọlọ́run.”
34 John eo, “Ayu aitinika naatu ao’orereb iti i God Natun.”
35 Ní ọjọ́ kejì, Johanu dúró pẹ̀lú méjì nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
35 Ana martot John iban maiye ana bai’ufununayah orot rou’ab bairi hina efan ta’imonamaim hibatabat.
36 Nígbà tí ó sì rí Jesu bí ó ti ń kọjá lọ, ó wí pé, “Wò ó Ọ̀dọ́-àgùntàn Ọlọ́run!”
36 Naatu Jesu na natabirih inan i’itin anamaramaim, John eo, “God ana Lamb enan kwa’itin!”
37 Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn méjì náà sì gbọ́ ohun tí ó wí yìí, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sì í tọ Jesu lẹ́yìn.
37 Anamaramaim bai’ufununayah orot rou’ab iti hinonowar, i hairi Jesu hi’ufunun.
38 Nígbà náà ni Jesu yípadà, ó rí i pé wọ́n ń tọ òun lẹ́yìn, ó sì béèrè pé, “Kí ni ẹ̀yin ń wá?”
38 Jesu nunutabir, orot rou’ab hibi’ufunun itih naatu ibatiyih, “Kwa abistan kwakokok?”
39 Ó wí fún wọn pé, “Ẹ wá wò ó, ẹ̀yin yóò sì rí i.”
39 I iya’afutih eo, “Kwanatan, kwa taiyuw efan kwa’itin.”
40 Anderu arákùnrin Simoni Peteru jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn méjì tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ Johanu, tí ó sì tọ Jesu lẹ́yìn.
40 John abistan eo’o orot rou’ab hinowar Jesu hibi’ufunun orot ta i Andrew, Simon Peter tain
41 Ohun àkọ́kọ́ tí Anderu ṣe ni láti wá Simoni arákùnrin rẹ̀, ó sì wí fún un pé, “Àwa ti rí Messia” (ẹni tí ṣe Kristi).
41 Andrew Jesu bihamiy ufunamaim wantoro’ot i tuwah Simon nuwih, naatu tita’ur ana tur eowen, “Ayu i Roubininenayan atita’ur, nati i Keriso.”
42 Ó sì mú un wá sọ́dọ̀ Jesu.
42 Naatu Andrew tuwah Simon nawiy in Jesu biyan tit.
43 Ní ọjọ́ kejì Jesu ń fẹ́ jáde lọ sí Galili, ó sì rí Filipi, ó sì wí fún un pé, “Máa tọ̀ mí lẹ́yìn.”
43 Ana marto, Jesu au Galilee namih bobogaigiwas, Philip tita’ur naatu iu, “Kuna kwi’ufnunu tan.”
44 Filipi gẹ́gẹ́ bí i Anderu àti Peteru, jẹ́ ará ìlú Betisaida.
44 Philip ana tafaram i Betsaida, Andrew tuwah Peter bairi hai bar merar ta’imon.
45 Filipi rí Natanaeli, ó sì wí fún un pé, “Àwa ti rí ẹni náà tí Mose kọ nípa rẹ̀ nínú òfin àti ẹni tí àwọn wòlíì ti kọ̀wé rẹ̀, Jesu ti Nasareti, ọmọ Josẹfu.”
45 Philip na Nathanael tita’ur naatu iu, “Iti orot isan Moses Buka Atamaninamaim eo kikirum naatu dinab oro’orot auman hikikirum i boun atita’ur, iti orot tamah i Joseph ana bar ana merar i Nazareth.”
46 Natanaeli béèrè pé, “Nasareti? Ohun rere kan ha lè ti ibẹ̀ jáde?”
46 “Nazareth! Sawar gewasin ta boro imaim namatar?” Nathanael ibat.
47 Jesu rí Natanaeli ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ̀, ó sì wí nípa rẹ̀ pé, “Èyí ni ọmọ Israẹli tòótọ́, nínú ẹni tí ẹ̀tàn kò sí.”
47 Anamaramaim Jesu nuw Nathanael nan itin, isan eo, “I turobe Israel mowan, i orot ana yawas gewasin men baifufuwenayan.”
48 Natanaeli béèrè pé, “Báwo ni ìwọ ti ṣe mọ̀ mí?”
48 Nathanael ibatiy, “O mi’itube ayu isu’ubu?”
49 Nígbà náà ni Natanaeli sọ ọ́ gbangba pé, “Rabbi, ìwọ ni Ọmọ Ọlọ́run; Ìwọ ni ọba Israẹli.”
49 Imaibo Nathanael eorereb eo, “Rabbi, Bai’obaiyenayan o i God Natun! o i Israel hai Aiwob.”
50 Jesu sì wí fún un pé, “Ìwọ gbàgbọ́ nítorí mo wí fún ọ pé mo rí ọ lábẹ́ igi ọ̀pọ̀tọ́. Ìwọ ó rí ohun tí ó pọ̀jù ìwọ̀nyí lọ.”
50 Jesu eo, “O i tumatum anayabin ayu a tur aowen o i ai fig an ima’am ait. O boro sawar gagamihika ina’itan men iti i’i’itin na’atube.”
51 Nígbà náà ni ó fi kún un pé, “Èmi wí fún yín nítòótọ́, ẹ̀yin yóò rí ọ̀run ṣí sílẹ̀, àwọn angẹli Ọlọ́run yóò sì máa gòkè, wọ́n ó sì máa sọ̀kalẹ̀ sórí Ọmọ Ènìyàn.”
51 Tur tafan ya’abar maiye eo, “Turobe a tur ao’owen, kwa boro mar ana etawan nabotawiy, naatu God ana tounamatar Orot Natun biyanamaim hinayen hinarara’iy kwana’itih.”

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar João 1, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.