João 16
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 “Nǹkan wọ̀nyí ni mo ti sọ fún yín, kí a má ba à mú yín yapa kúrò.
1 “Sawar etei’imak i ao kwanowar sawar, saise kwa boro men ef kwanarukasiy.
2 Wọ́n ó yọ yín kúrò nínú Sinagọgu: àní, àkókò ń bọ̀, tí ẹnikẹ́ni tí ó bá pa yín, yóò rò pé òun ń ṣe ìsìn fún Ọlọ́run.
2 Jew hai Kou’ay Bar wanawanan boro hinanuni ufun kwanatit, veya nanan anamaramaim o yait ta na’a’asbuni, i boro asir nanot God ana sibor eya’iy narouw.
3 Nǹkan wọ̀nyí ni wọ́n ó sì ṣe, nítorí tí wọn kò mọ Baba, wọn kò sì mọ̀ mí.
3 Sabuw boro kakafin isa hinasinaf, anayabin Tamat men hisu’ub naatu ayu auman men hisu’ubu.
4 Ṣùgbọ́n nǹkan wọ̀nyí ni mo ti sọ fún yín, pé nígbà tí wákàtí wọn bá dé, kí ẹ lè rántí wọn pé mo ti wí fún yín. Ṣùgbọ́n èmi kò sọ nǹkan wọ̀nyí fún yín láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ wá, nítorí tí mo wà pẹ̀lú yín.
4 Ayu kwa a tur ao’owen, saise ana veya nanan kwa boro kwananot ayu i ai’matnuwi sawar, anayabin ayu kwa bairit tama’am isan, men saise a tur aowenamih.
5 “Ṣùgbọ́n nísinsin yìí èmi ń lọ sọ́dọ̀ ẹni tí ó rán mi; kò sì sí ẹnìkan nínú yín tí ó bi mí lérè pé, ‘Níbo ni ìwọ ń lọ?’
5 “Boun ayu amatabir maiye anan, yait ayu iyunu anan i biyan anatit, naatu men yait ta ayu ibatiyu’umih, ‘O menika kwenan’
6 Ṣùgbọ́n nítorí mo sọ nǹkan wọ̀nyí fún yín, ìbìnújẹ́ kún ọkàn yín.
6 Anayabin ayu tur iti ao isan, kwa yababan yen bufuti.
7 Ṣùgbọ́n òtítọ́ ni èmi ń sọ fún yín; àǹfààní ni yóò jẹ́ fún yín bí èmi bá lọ, nítorí bí èmi kò bá lọ, Olùtùnú kì yóò tọ̀ yín wá; ṣùgbọ́n bí mo bá lọ, èmi ó rán an sí yín.
7 Baise turobe a tur ao’owen. Iti i kwa a gewasin isan ayu amamatabir maiye. Ayu men ananan na’at, Baibaisayan boro men nan, baise ayu ananan i boro aniyun nan kwa isa.
8 Nígbà tí òun bá sì dé, yóò fi òye yé aráyé ní ti ẹ̀ṣẹ̀, àti ní ti òdodo, àti ní ti ìdájọ́,
8 I nanan ana maramaim sabuw iti tafaram ana kakafinamaim hima tesisinaf nabotabirih hinan yawas roumutuforen hinab naatu God ana baibabatiyen saise hinaso’ob gewas.
9 ní ti ẹ̀ṣẹ̀, nítorí tí wọn kò gbà mí gbọ́;
9 sabuw ayu men tebitutumu anayabin i kakafin wanawanan tema’am;
10 ní ti òdodo, nítorí tí èmi ń lọ sọ́dọ̀ Baba, ẹ̀yin kò sì mọ̀ mí.
10 naatu tenotanot roumutufuren i kakafin terarouw, anayabin ayu anan Tamai biyan, naatu boro men kwana’itu maiye;
11 Ní ti ìdájọ́, nítorí tí a ti ṣe ìdájọ́ ọmọ-aládé ayé yìí.
11 naatu baibabatiyen i boro nan, anayabin God marasika iti tafaram ana kaifenayan i ibabatiy sawar.
12 “Mo ní ohun púpọ̀ láti sọ fún yín pẹ̀lú, ṣùgbọ́n ẹ kò lè gbà wọ́n nísinsin yìí.
12 “Ayu auru tur moumurin maiyow boro atao kwatanowar, baise boun kwa isa ana’o boro men naniyan kwanab.
13 Ṣùgbọ́n nígbà tí òun, àní Ẹ̀mí òtítọ́ náà bá dé, yóò tọ́ yín sí ọ̀nà òtítọ́ gbogbo, nítorí kì yóò sọ ti ara rẹ̀; ṣùgbọ́n ohunkóhun tí ó bá gbọ́, òun ni yóò máa sọ, yóò sì sọ ohun tí ń bọ̀ fún yín.
13 Baise anamaramaim turobe ana Anun Kakafiyin nanan, i Boro turobe ana ef etei nabonawiyi. I boro men taiyuwin ana notamaim na’omih, abistanawat enonowar i akisinamo nao, naatu sawar uf hinamamatar isan boro a tur na’owen.
14 Òun ó máa yìn mí lógo, nítorí tí yóò gbà nínú ti èmi, yóò sì máa sọ ọ́ fún yín.
14 Ayu boro nabora’ara’ahu, anayabin ayu au tur biyau’une bai na kwa a tur eo’owen isan.
15 Ohun gbogbo tí Baba ní tèmi ni, nítorí èyí ni mo ṣe wí pé, òun ó gba nínú tèmi, yóò sì sọ ọ́ fún yín.
15 Sawar etei ayu Tamai biyan tema’am i ayu nowau naatu abistan ayu biyau ema’am boro Anun Kakafiyin nab nan niwa’an kwa isa nirerereb, anayabin iti isan kwa a tur ao’owen.
16 “Nígbà díẹ̀, ẹ̀yin kì ó sì rí mi, àti nígbà díẹ̀ si, ẹ ó sì rí mi, nítorí tí èmi ń lọ sọ́dọ̀ Baba.”
16 “Mar kikimin kwa boro men ayu kwana’itu naatu mar kafai kikimin kwa boro ayu kwana’itu.
17 Nítorí náà díẹ̀ nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń bá ara wọn sọ pé, “Kín ni èyí tí o wí fún wa yìí, ‘Nígbà díẹ̀, ẹ̀yin ó sì rí mi, àti nígbà díẹ̀ ẹ̀wẹ̀, ẹ̀yin kì yóò rí mi, àti, nítorí tí èmi ń lọ sọ́dọ̀ Baba’?”
17 Ana bai’ufununayah afa taiyuwih hima hibabatiyih? “Anayabin abistan isan i tur iti na’atube eo, ‘Mar kikimin kwa boro men kwana’itu, naatu mar kafai ufunamaim ayu boro kwana’itu’ naatu ‘Anayabin ayu anan Tamai biyan?’
18 Nítorí náà wọ́n wí pé, kín ni, nígbà díẹ̀? Àwa kò mọ̀ ohun tí ó wí.
18 Naatu i hima hi’o hibabatiyih, Iti anayabin nam abisa isan eo’o, ‘Iti mar kikimin?’ Aki men aso’ob i abistan eo’o.”
19 Jesu sá à ti mọ̀ pé, wọ́n ń fẹ́ láti bi òun léèrè, ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ń bi ara yín léèrè ní ti èyí tí mo wí pé, nígbà díẹ̀, ẹ̀yin kì yóò sì rí mi, àti nígbà díẹ̀ si, ẹ̀yin ó sì rí mi?
19 Jesu itih so’ob iti isan boro hinibatiy, imih i isah eo, “Ayu iti tur ao isan kwa tayuwiwat kwama kwabibabatiyi anayabin isan, anamaramaim ayu iti na’at ao, ‘Mar kikimin ayu boro men kwana’itu, naatu mar kafai ufunamaim ayu boro kwana’itu.’
20 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín pé, ẹ̀yin yóò máa sọkún ẹ ó sì máa pohùnréré ẹkún, ṣùgbọ́n àwọn aráyé yóò máa yọ̀: ṣùgbọ́n, ìbànújẹ́ yín yóò di ayọ̀.
20 Ayu anababatun a tur ao’owen, Kwa boro kwanarererey naatu kwanigagamat baise tafaram naben nakawasa. Kwa boro kwaniyababan, baise kwa a yababan boro nabotabir yasisir namatar.
21 Nígbà tí obìnrin bá ń rọbí, a ní ìbìnújẹ́, nítorí tí wákàtí rẹ̀ dé: ṣùgbọ́n nígbà tí ó bá ti bí ọmọ náà tán, òun kì í sì í rántí ìrora náà mọ́, fún ayọ̀ nítorí a bí ènìyàn sí ayé.
21 Babin anatoub ana veya nakabom ebiyababan na’atube anayabin biyababan ana veya i na kabom; baise anamaramaim kek tufuw, i ana biyababan inatbuhuruw anayabin kek tafaramamaim tufuw i ebiyasisir.
22 Nítorí náà ẹ̀yin ní ìbànújẹ́ nísinsin yìí, ṣùgbọ́n èmi ó tún rí yín, ọkàn yín yóò sì yọ̀, kò sì sí ẹni tí yóò gba ayọ̀ yín lọ́wọ́ yín.
22 Imih kwa auman. Boun i kwa a veya kwaniyababan, baise ayu boro kwa ana’iti maiye naatu kwaniyasisir naatu men karam yait ta kwa a yasisir biyane nabosair.
23 Àti ní ọjọ́ náà ẹ̀yin kì ó bi mí lérè ohunkóhun. Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ohunkóhun tí ẹ̀yin bá béèrè lọ́wọ́ Baba ní orúkọ mi, òhun ó fi fún yín.
23 Nati anamaramaim o men yait ta ayu isou sawaramih inafefeyan. Tur anababatun a tur ao’owen, sawar abistan isan ayu wabu’umaim inabifefeyan, ayu Tamai boro nit.
24 Títí di ìsinsin yìí ẹ kò tí ì béèrè ohunkóhun ní orúkọ mi, ẹ béèrè, ẹ ó sì rí gbà, kí ayọ̀ yín kí ó lè kún.
24 Marasika na iti boun kwa men yait ta iti na’atube ayu wabu’umaim fefeyanamih. Boun kwanafefeyan, naatu kwa boro kwanab, naatu kwa boro mar etei yasisiramaim kwanama.
25 “Nǹkan wọ̀nyí ni mo fi òwe sọ fún yín: ṣùgbọ́n àkókò dé, nígbà tí èmi kì yóò fi òwe bá yín sọ̀rọ̀ mọ́, ṣùgbọ́n èmi ó sọ nípa ti Baba fún yín gbangba.
25 “Ayu mar etei kawen turamaim ao kwanowar sawar, mar i enan ayu boro men kafa’imo kawen turamaim anao, baise ayu Tamai isan i boro mutufor bebeyanamaim anao kwananowar,
26 Ní ọjọ́ náà, ẹ̀yin ó béèrè ní orúkọ mi, èmi kò sì wí fún yín pé, èmi ó béèrè lọ́wọ́ Baba fún yín.
26 Nati ana veya’amaim kwa boro ayu wabu’umaim kwanafefeyan. Ayu ao i men kwa au kou anabat Tamai anifefeyanimih.
27 Nítorí tí Baba tìkára rẹ̀ fẹ́ràn yín, nítorí tí ẹ̀yin ti fẹ́ràn mi, ẹ sì ti gbàgbọ́ pé, lọ́dọ̀ Ọlọ́run ni èmi ti jáde wá.
27 Aiyabin, Tamai i taiyuwin kwa isa ebiyabow, anayabin kwa ayu isou kwabiyabow naatu kwabitumatum ayu i God iyafaru ana.
28 Mo ti ọ̀dọ̀ Baba jáde wá, mo sì wá sí ayé, àti nísinsin yìí mo fi ayé sílẹ̀, mo sì lọ sọ́dọ̀ Baba.”
28 Ayu Tamai iyafaru ana, tafaram wanawanan arun abow aremor, boun ayu tafaram abihamiy naatu anan Tamai biyan.
29 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wí fún un pé, “Wò ó, nígbà yìí ni ìwọ ń sọ̀rọ̀ gbangba, ìwọ kò sì sọ ohunkóhun ní òwe.
29 Naatu Jesu ana bai’ufununayah hi’o, “Bounabo tur bebeyanamaim ku’o’o naatu men kawenamaim ku’o’omih.
30 Nígbà yìí ni àwa mọ̀ pé, ìwọ mọ̀ ohun gbogbo, ìwọ kò ní kí a bi ọ́ léèrè: nípa èyí ni àwa gbàgbọ́ pé, lọ́dọ̀ Ọlọ́run ni ìwọ ti jáde wá.”
30 Bounabo aki mataito’iwa’an a’i’itin o sawar etei i so’ob, naatu o men yait ta kukokok boro o isa baibat nabow natit. Aki iti’imaim i’obaiyi abitumatum o i Godane ina.”
31 Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ẹ̀yin gbàgbọ́ wàyí?
31 Jesu iyafutih eo, “Kwa bounabo kwabitumatum?”
32 Kíyèsi i, wákàtí ń bọ̀, àní ó dé tan nísinsin yìí, tí a ó fọ́n yín ká kiri, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀; ẹ ó sì fi èmi nìkan sílẹ̀, ṣùgbọ́n kì yóò sì ṣe èmi nìkan, nítorí tí Baba ń bẹ pẹ̀lú mi.
32 “Baise veya i enan, naatu na titaka, anamaramaim kwa boro na’abargiyi taiyuw a bar a merar na’at kwanabihir. Ayu boro kwanihamiyu nakutatabu ana bat. Baise ayu men akisu anayabin Tamai ayu airi ama’am.
33 “Nǹkan wọ̀nyí ni mo ti sọ fún yín tẹ́lẹ̀, kí ẹ̀yin kí ó lè ní àlàáfíà nínú mi. Nínú ayé, ẹ̀yin ó ní ìpọ́njú; ṣùgbọ́n ẹ tújúká; mo ti ṣẹ́gun ayé.”
33 “Ayu sawar etei ao kwanowaraka, saise ayu wanawana’umaim kwanama’am kwa karam boro tufuwamaim kwanama. Iti tafaramamaim kwa boro yare wanawanan kwanarun kwani’akir. Baise kwanafair kwanabat! Ayu Tafaram aigegesair.”
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar João 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.