João 15
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 “Èmi ni àjàrà tòótọ́, Baba mi sì ni olùṣọ́gbà.
1 “Ayu i ai an anababatun, naatu Tamai i masaw Matuwan.
2 Gbogbo ẹ̀ka nínú mi tí kò bá so èso, òun a mú kúrò, gbogbo ẹ̀ka tí ó bá sì so èso, òun a wẹ̀ ẹ́ mọ́, kí ó lè so èso sí i.
2 Ayu famufamu ro’oro’on men ebiw gewas boro na’afuw nisaroun, naatu ro’oro’on ebiw gewas boro famufamu natobubunei saise ro’o’ro’on moumurihika niw naya.
3 Ẹ̀yin mọ́ nísinsin yìí nítorí ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ fún yín.
3 Kwa i marasika kwaigewasin sawar, anayabin ayu turamaim ao kwanowar sawar.
4 Ẹ máa gbé inú mi, èmi ó sì máa gbé inú yín. Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ka kò ti lè so èso fún ara rẹ̀ bí kò ṣe pé ó ba ń gbé inú àjàrà, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin, bí kò ṣe pé ẹ bá ń gbé inú mi.
4 Wanawana’umaim kwanitubonen kwanama, naatu ayu kwa wanawanamaim anitubonen anama. Famen akisin men karam taiyuwin niw ro’on nayai, baise i boro ai naiwan nituw. Ef ta’imon kwa ayu wanawanau kwanitubonen boro ro’oro’o moumurihika kwanaya.
5 “Èmi ni àjàrà, ẹ̀yin ni ẹ̀ka. Ẹni tí ó ń gbé inú mi, àti èmi nínú rẹ̀, òun ni yóò so èso lọ́pọ̀lọ́pọ̀, nítorí ní yíya ara yín kúrò lọ́dọ̀ mi, ẹ kò lè ṣe ohun kan.
5 “Ayu i ai, naatu kwa i ai famefamen, o yait ayu wanawana’umaim inabituwabon naatu ayu o wanawananamaim anabituwabon, i boro ro’oro’o moumurihika naya; anayabin, o akis men karam boro inasinaf namatar.
6 Bí ẹnìkan kò bá gbé inú mi, a gbé e sọnù gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ka, a sì gbẹ; wọn a sì kó wọn jọ, wọn a sì sọ wọ́n sínú iná, wọn a sì jóná.
6 O yait ta ayu airit men tanibitubonen na’at, i boun ai famefamen hituw batabat kekerer na’atube, nati boro hina’o’on wairaf wan hinaroura’aten hinikubaren hina’arat.
7 Bí ẹ̀yin bá ń gbé inú mi, tí ọ̀rọ̀ mi bá sì gbé inú yín, ẹ ó béèrè ohunkóhun tí ẹ bá fẹ́, a ó sì ṣe é fún yín.
7 O yait ayu wanawana’umaim inabitubonen naatu ayu au tur o wanawanamaim nabitubonen na’at, o a kok abistan isan kufefefeyan o boro anit.
8 Nínú èyí ní a yìn Baba mi lógo pé, kí ẹ̀yin kí ó máa so èso púpọ̀; ẹ̀yin ó sì jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn mi.
8 Kwa ro’oro’o moumurihika kwanaya’ay kwa boro taiyuw kwana’inani, kwa i ayu au bai’ufununayah naatu Tamai ana gewasin boro sabuw kwani’obaiyih.
9 “Gẹ́gẹ́ bí Baba ti fẹ́ mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi sì fẹ́ yín, ẹ dúró nínú ìfẹ́ rẹ̀.
9 Tamai ebiyabuwu na’atube; kwa abiyabuwi. Au yabowamaim kwanitubonen kwanama.
10 Bí ẹ̀yin bá pa òfin mi mọ́, ẹ ó dúró nínú ìfẹ́ mi; gẹ́gẹ́ bí èmi ti pa òfin Baba mi mọ́, tí mo sì dúró nínú ìfẹ́ rẹ̀.
10 Kwa ayu ou’obaiyunen tur kwanabobosiyasiyar na’at, boro ayu au yabowamaim kwanitubonen kwanama, boun ayu Tamai ana’obaiyunen tur abosiyasiyar naatu i ana yabowamaim aitubonen ama’am na’atube.
11 Nǹkan wọ̀nyí ni mo ti sọ fún yín, kí ayọ̀ mi kí ó lè wà nínú yín, àti kí ayọ̀ yín kí ó lè kún.
11 “Ayu a tur aowen kwanowar sawar saise au yasisir kwa wanawanamaim nama, naatu kwa mar etei yasisiramaim kwanama.
12 Èyí ni òfin mi, pé kí ẹ̀yin kí ó fẹ́ràn ara yín, gẹ́gẹ́ bí mo ti fẹ́ràn yín.
12 Ayu au obaiyunen tur i iti. Turanah bairi kwaniyabowbonen, ayu kwa abiyabuwi na’atube.
13 Kò sí ẹnìkan tí ó ní ìfẹ́ tí ó tóbi ju èyí lọ, pé ẹnìkan fi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ nítorí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀.
13 Yait ta ana ofonah isah namomorob na’at, nati ebi’obaiy i ana yabow ra’at kwanekwan.
14 Ọ̀rẹ́ mi ni ẹ̀yin ń ṣe, bí ẹ bá ṣe ohun tí èmi pàṣẹ fún yín.
14 Ayu obaiyunen tur abistan sinaf isan ou’uwi, i kwanasisinaf na’at, kwa i ayu au ofonah.
15 Èmi kò pè yín ní ọmọ ọ̀dọ̀ mọ́; nítorí ọmọ ọ̀dọ̀ kò mọ ohun tí olúwa rẹ̀ ń ṣe, ṣùgbọ́n èmi pè yín ní ọ̀rẹ́ nítorí ohun gbogbo tí mo ti gbọ́ láti ọ̀dọ̀ Baba mi wá, mo ti fihàn fún yín.
15 Ayu boro men kafa’imo kwa isa akir anarouw ana’af, anayabin akir orot i men so’ob ana orot ukwarin abistan esisinaf. Nati efanin ayu kwa isa au ofonah arouw ao’o, anayabin ayu Tamai biyanane tur abistanawat anonowar etei’imak a tur aowen kwanowar sawar.
16 Kì í ṣe ẹ̀yin ni ó yàn mí, ṣùgbọ́n èmi ni ó yàn yín, mo sì fi yín sípò, kí ẹ̀yin kí ó lè lọ, kí ẹ sì so èso, àti kí èso yín lè dúró; kí ohunkóhun tí ẹ bá béèrè lọ́wọ́ Baba ní orúkọ mi, kí ó lè fi í fún yín.
16 Kwa men ayu kwarubinu, ayu kwa arubini naatu atarbaiyuni kwanatit kwanan kwaniw ro’oro moumurihika kwanaya–nati ro’o’ro’on boro men hinamun. Naatu abistan isan ayu wabu’umaim kwafefefeyan Tamai boro nit.
17 Nǹkan wọ̀nyí ni mo pàṣẹ fún yín pé, kí ẹ̀yin kí ó fẹ́ràn ara yín.
17 Iti i ayu ou’obaiyunen tur. Turanah bairi kwaniyabowbonen.
18 “Bí ayé bá kórìíra yín, ẹ mọ̀ pé, ó ti kórìíra mi ṣáájú yín.
18 “Kwa sabuw hinabifutuwi na’at, kwa kwanaso’ob nati ayu wan ifutuwu’ubo kwa uf ifutuw.
19 Ìbá ṣe pé ẹ̀yin ń ṣe ti ayé, ayé ìbá fẹ́ yin bi àwọn tirẹ̀; gẹ́gẹ́ bi o ṣe ri tí ẹ̀yin kì ń ṣe ti ayé, ṣùgbọ́n èmi ti yàn yín kúrò nínú ayé, nítorí èyí ni ayé ṣe kórìíra yín.
19 Kwa tafaram nowan kwanama’am na’at, tafaram boro niyabuwi nowan na’atube kwanamatar kwanama, kwa i men iti tafaram nowan, baise kwa tafaramane arubini abotaiti kwatit. Nati isan tafaram kwa ebifutuwi.
20 Ẹ rántí ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ fún yín pé, ‘Ọmọ ọ̀dọ̀ kò tóbi ju olúwa rẹ̀ lọ.’ Bí wọ́n bá ti ṣe inúnibíni sí mi, wọ́n ó ṣe inúnibíni sí yín pẹ̀lú: bí wọ́n bá ti pa ọ̀rọ̀ mi mọ́, wọ́n ó sì pa tiyín mọ́ pẹ̀lú.
20 Iti tur kwa isa ao’o i a notamaim nama. ‘Orot ana bowayan i men ra’at ana orot ukwarin natabirimih.’ Kwa hinarabi hinabi’a’afiyi na’at, ayu auman hirabu tibi’afiyu. Ayu au bai’obaiyen hinabobosiyasiyar na’at, kwa auman boro hinabosiyasiyari.
21 Ṣùgbọ́n gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni wọ́n yóò ṣe sí yín, nítorí orúkọ mi, nítorí tí wọn kò mọ ẹni tí ó rán mi.
21 Ayu wabu isan, kwa isa boro iti na’atube hinamatar. anayabin i men hiso’ob yait ayu iyunu ana.
22 Ìbá ṣe pé èmi kò ti wá kí n sì ti bá wọn sọ̀rọ̀, wọn kì bá tí ní ẹ̀ṣẹ̀, ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n di aláìríwí fún ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
22 Ayu men atan biyah atatit naatu tur gewasin men atao hitanonowar na’at, kakafin isan boro men ubar hitabaimih; baise boun boro men hai kakafin isan hinifufuwenamih.
23 Ẹni tí ó bá kórìíra mi, ó kórìíra Baba mi pẹ̀lú.
23 Yait ayu ebifutuwu Tamai auman i ebifutuw.
24 Ìbá ṣe pé èmi kò ti ṣe iṣẹ́ wọ̀n-ọn-nì láàrín wọn tí ẹlòmíràn kò ṣe rí, wọn kì bá tí ní ẹ̀ṣẹ̀, ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n sì rí, wọ́n sì kórìíra èmi àti Baba mi.
24 Ayu wanawanahimaim asisinaf men yait ta sisinaf na’atube asinafumih, imih i boro men kakafin hitasinaf. Baise boun ina’inan hi’itah, naatu ayu Tamai airi’ika hikwahiri.
25 Ṣùgbọ́n èyí rí bẹ́ẹ̀ kí ọ̀rọ̀ tí a kọ nínú òfin wọn kí ó lè ṣẹ pé, ‘Wọ́n kórìíra mi ní àìnídìí.’
25 Baise iti mamatar, i abistanawat hai ofafaramaim hi’o hikikirum i na iturobe, Anayabin en ayu hifutuwu.
26 “Ṣùgbọ́n nígbà tí Olùtùnú náà bá dé, ẹni tí èmi ó rán sí yín láti ọ̀dọ̀ Baba wá, àní Ẹ̀mí òtítọ́ nì, tí ń ti ọ̀dọ̀ Baba wá, òun náà ni yóò jẹ́rìí mi.
26 “Ayu boro Baibaisayan aniyafar nan, nati i turobe ana Anun Kakafiyin, i boro Tamai biyanane niyafar nan kwa biya natit, naatu ayu isou boro nao rerereb.
27 Ẹ̀yin pẹ̀lú yóò sì jẹ́rìí mi, nítorí tí ẹ̀yin ti wà pẹ̀lú mi láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ wá.
27 naatu kwa auman boro ayu isou kwana’orerereb, anayabin no aneika kwa ayu bairit tama.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar João 15, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.