João 14

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 “Ẹ má ṣe jẹ́ kí ọkàn yín kí ó dàrú, ẹ gba Ọlọ́run gbọ́, kí ẹ sì gbà mí gbọ́ pẹ̀lú.
1 Jesu ana bai’ufununayah isa eo, “Men kwaniyababan, God kwanitumatum naatu ayu auman kwanitutumu.
2 Nínú ilé Baba mi ọ̀pọ̀lọpọ̀ ibùgbé ni ó wà, ìbá má ṣe bẹ́ẹ̀, èmi ìbá tí sọ fún yín. Èmi ń lọ láti pèsè ààyè sílẹ̀ fún yín.
2 Ayu Tamai ana baremaim bar awah moumurih na’in ti’inu’in naatu ayu anan kwa isa a bar awah anayabuna naatu bar awah men hitama’am na’at, aisim boro a tur ata’owen.
3 Bí mo bá sì lọ láti pèsè ààyè sílẹ̀ fún un yín, èmi ó tún padà wá, èmi ó sì mú yín lọ sọ́dọ̀ èmi tìkára mi; pé níbi tí èmi gbé wà, kí ẹ̀yin lè wà níbẹ̀ pẹ̀lú.
3 Ayu anan kwa a efan anayayabuna ufunamaim boro taiyuwu anamatabir anan ananawiyi bairi tanan ayu menamaim ama’am kwa boro imaim kwanama.
4 Ẹ̀yin mọ ibi tí èmi gbé ń lọ, ẹ sì mọ ọ̀nà náà.”
4 Ayu efan menamaim anan kwa i kwaso’ob.”
5 Tomasi wí fún un pé, “Olúwa, a kò mọ ibi tí ìwọ ń lọ, a ó ha ti ṣe mọ ọ̀nà náà?”
5 Thomas Jesu isan eo, “Regah, aki men aso’ob o menamaim kwenan, ef boro mi’itube anaso’ob?”
6 Jesu dá wọn lóhùn pé, “Èmi ni ọ̀nà, òtítọ́ àti ìyè, kò sí ẹnikẹ́ni tí ó lè wá sọ́dọ̀ Baba, bí kò ṣe nípasẹ̀ mi.
6 Jesu iya’afut eo, “Ayu i ef, turobe, naatu yawas. Men yait ta nan Tamai biyan baise ayu’une nan Tamai biyan natit.
7 Ìbá ṣe pé ẹ̀yin ti mọ̀ mí, ẹ̀yin ìbá ti mọ Baba mi pẹ̀lú, láti ìsinsin yìí lọ ẹ̀yin mọ̀ ọ́n, ẹ sì ti rí i.”
7 Kwa anababatun ayu kwanasusu’ubu gewas na’at, Tamai boro auman kwanasu’ub. Bounabo kwasoso’ob naatu kwa’i’itin.”
8 Filipi wí fún un pé, “Olúwa, fi Baba náà hàn wá, yóò sì tó fún wa.”
8 Philip eo, “Regah Tamat kwi’obaiyi a’itin saise aki boro nuhinafot.”
9 Jesu wí fún un pé, “Bí àkókò tí mo bá yín gbé ti tó yìí, ìwọ, kò sì tí ì mọ̀ mí síbẹ̀ Filipi? Ẹni tí ó bá ti rí mi, ó ti rí Baba. Ìwọ ha ti ṣe wí pé, ‘Fi Baba hàn wá!’
9 Jesu iya’afut eo, “Philip manin maiyow airit tama baise men isu’ubu? Yait ta ayu i’itu Tamai i’itin? Aisimamih ayu isou i’o, ‘Tamat kwi’obaiyi a’itin?’
10 Ìwọ kò ha gbàgbọ́ pé, èmi wà nínú Baba, àti pé Baba wà nínú mi? Ọ̀rọ̀ tí èmi ń sọ fún yín, èmi kò dá a sọ; ṣùgbọ́n Baba ti ó wà nínú mi, òun ní ń ṣe iṣẹ́ rẹ̀.
10 Ayu i Tamai wanawananamaim ama’am naatu Tamai ayu wanawana’umaim ema’am. Philip o men kubitumatum? Iti tur i kwa isa ao’o, i men ayu au kokomaim ao’omih baise Tamai ayu wanawana’umaim ema’am bowabow i esisinaf.
11 Ẹ gbà mí gbọ́ pé, èmi wà nínú Baba, Baba sì wà nínú mi, bí kò ṣe bẹ́ẹ̀, ẹ gbà mí gbọ́ nítorí àwọn ẹ̀rí iṣẹ́ náà pàápàá!
11 Kwanitumatum ana maramaim iti tur anao’o, ayu i Tamai wanawanan ama’am naatu Tamai i ayu wanawanau ema’am, o men kwanabitumatum na’at ina’inan asisinaf imaim boro ni’obaiyi kwana’itin.
12 Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́, iṣẹ́ tí èmi ń ṣe ni òun yóò ṣe pẹ̀lú; iṣẹ́ tí ó tóbi ju wọ̀nyí lọ ni yóò sì ṣe; nítorí tí èmi ń lọ sọ́dọ̀ Baba.
12 Ayu anababatun a tur ao’owen yait ayu ebitutumu ayu abistan asisinaf boro nasinaf hinamatar, naatu sawar boro au gagamihika nasinaf. Anayabin ayu Tamai isan anan.
13 Ohunkóhun tí ẹ̀yin bá sì béèrè ní orúkọ mi, òun náà ni èmi ó ṣe, kí a lè yin Baba lógo nínú Ọmọ.
13 Naatu abistanawat ayu wabu’umaim kwafefefeyan boro ana sinaf saise Natun Tamah wabin nabora’ara’ah.
14 Bí ẹ̀yin bá béèrè ohunkóhun ní orúkọ mi, èmi ó ṣe é.
14 Kwa sawar abistanawat ayu wabu’umaim kwanafefeyan boro anasinaf namatar.
15 “Bí ẹ̀yin bá fẹ́ràn mi, ẹ ó pa òfin mi mọ́.
15 “Ayu kwanabiyabuwu na’at, au obaiyunen tur boro kwanabosiyasiyar.
16 Nígbà náà èmi yóò wá béèrè lọ́wọ́ Baba. Òun yóò sì fún yín ní olùtùnú mìíràn. Olùtùnú náà yóò máa bá yín gbé títí láé.
16 Naatu ayu boro Tamai anifefeyan i boro kwa a Baibaisayan ta wabin Turobe Ana Anun Kakafiyin nit bairi kwanama wanatowan.
17 Òun ni Ẹ̀mí òtítọ́. Ayé kò le gbà á. Nítorí ayé kò mọ̀ ọ́n, bẹ́ẹ̀ ni kò rí i rí. Ẹ̀yin mọ̀ ọn nítorí láti ìgbà tí ẹ ti wà pẹ̀lú mí. Òun náà ti wà pẹ̀lú yín. Ṣùgbọ́n ní ọjọ́ kan yóò wọ inú yín láti máa gbé ibẹ̀.
17 Iti tafaram men nab, anayabin i boro men na’itin o boro men nasu’ub. Baise kwa i kwasu’ub, anayabin kwa bairi kwama’am naatu boro wanawanamaim nama.
18 Èmi kò ní fi yín sílẹ̀ láìní Olùtùnú, kí ẹ ma dàbí ọmọ tí kò ní òbí. Rárá o! Mo tún ń tọ̀ yín bọ̀.
18 Ayu boro men anihamiyi kwanigaganamih, Ayu boro kwa isa anamatabir maiye anan.
19 Nígbà díẹ̀ sí i, ayé kì yóò rí mi mọ́; ṣùgbọ́n ẹ̀yin yóò rí mi, nítorí tí èmi wà láààyè, ẹ̀yin yóò wà láààyè pẹ̀lú.
19 Mar kafai iti tafaram boro men na’itu, baise kwa boro kwana’itu. Anayabin ayu ama’am isan kwa auman kwama’am.
20 Ní ọjọ́ náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, èmi wà nínú Baba mi, àti ẹ̀yin nínú mi, àti èmi nínú yín.
20 Nati anamaramaim kwa boro kwanaso’ob ayu i Tamai wanawanan ama’am naatu kwa i ayu wanawanau kwama’am naatu ayu i kwa wanawan ama’am.
21 Ẹni tí ó bá ní òfin mi, tí ó bá sì ń pa wọ́n mọ́, òun ni ẹni tí ó fẹ́ràn mi, ẹni tí ó bá sì fẹ́ràn mi, a ó fẹ́ràn rẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Baba mi, èmi ó sì fẹ́ràn rẹ̀, èmi ó sì fi ara mi hàn fún un.”
21 “Yait obaiyunen tur bai, ebobosiyasiyar, i ayu ebiyabuwu. Yait ayu ebiyabuwu i Tamai ebiyabuw naatu ayu auman boro aniyabuw naatu ayu taiyuwu anirerereb i isan.”
22 Judasi (kì í ṣe Judasi Iskariotu) wí fún un pé, “Olúwa, èéha ti ṣe tí ìwọ ó fi ara rẹ hàn fún àwa, tí kì yóò sì ṣe fún aráyé?”
22 Judas (men Judas Iscariot) Jesu isan eo, “Regah aisimamih tafaram ana sabuw men isah inirerereb baise aki akisi isai inirerereb?”
23 Jesu dáhùn ó sì wí fún un pé, “Bí ẹnìkan bá fẹ́ràn mi, yóò pa ọ̀rọ̀ mi mọ́. Baba mi yóò sì fẹ́ràn rẹ̀, àwa ó sì tọ̀ ọ́ wá, a ó sì ṣe ibùgbé wa pẹ̀lú rẹ̀.
23 Jesu iya’afutih eo, “Yait ta ayu isou ebiyabow boro au bai’obaiyen nabosiyasiyar? Ayu Tamai boro isan niyabow, naatu ayu Tamai airi biyanamaim ai bar anawowab bairi anama.
24 Ẹni tí kò fẹ́ràn mi ni kò pa ọ̀rọ̀ mi mọ́. Ọ̀rọ̀ tí ẹ̀yin ń gbọ́ kì í ṣe ti èmi, ṣùgbọ́n ti Baba tí ó rán mi.
24 Yait ayu isou men ebiyabow au bai’obaiyen boro men nabosiyasiyar naatu iti tur ao kwanonowar i men ayu au turamih baise iti tur ayu Tamai iyafaru anan i biyanane enan.
25 “Nǹkan wọ̀nyí ni èmi ti sọ fún yín, nígbà tí mo ń bá yín gbé.
25 “Boun bairit tama’amamaim sawar etei’imak ao kwanowaraka.
26 Ṣùgbọ́n Olùtùnú náà, Ẹ̀mí Mímọ́, ẹni tí Baba yóò rán ní orúkọ mi, òun ni yóò kọ́ yín ní ohun gbogbo, yóò sì rán yín létí ohun gbogbo tí mo ti sọ fún yín.
26 Baise Baibaisayan, Anun Kakafiyin, boro Tamai niyun ayu wabu’umaim nan, i boro sawar etei ni’obaibiyi naatu sawar etei’imak au’uwi boro a not nakusisib.
27 Àlàáfíà ni mo fi sílẹ̀ fún yín pé, àlàáfíà mi ni mo fi fún yin, kì í ṣe bí ayé ti fi fún ni. Ẹ má ṣe jẹ́ kí ọkàn yín dàrú, ẹ má sì jẹ́ kí ó wárìrì.
27 “Tufuw kwa biyamaim abihamiy, ayu tufuw kwa abit. Iti tufuw i men tafaram kwa bit na’atube abitimih. Yare kouh kwanayey a not men narukasiy naatu men kwanabir.
28 “Ẹ̀yin sá ti gbọ́ bí mo ti wí fún yín pé, ‘Èmi ń lọ, èmi ó sì tọ̀ yín wá.’ Ìbá ṣe pé ẹ̀yin fẹ́ràn mi, ẹ̀yin ìbá yọ̀ nítorí èmi ń lọ sọ́dọ̀ Baba; nítorí Baba mi tóbi jù mí lọ.
28 Iti tur i ao kwanowaraka. ‘Ayu i anan kwa isa boro anamatabir anan.’ Ayu kwanabiyabuwu na’at, kwaniyasisir ayu i Tamai isan anan anayabin Tamai i ra’at ayu natabiru.
29 Èmi sì ti sọ fún yín nísinsin yìí kí ó tó ṣẹ, pé nígbà tí ó bá ṣẹ, kí ẹ lè gbàgbọ́.
29 Bounaika a tur ao’owenabo sawar hinamatar, imih abistan hinamamatar kwa i kwanitumatum.
30 Èmi kì yóò bá yín sọ̀rọ̀ púpọ̀, nítorí ọmọ-aládé ayé yí wá, kò sì ní nǹkan kan lòdì sí mi.
30 Ayu boro men tur manin bairit tanao, anayabin tafaram ana kaifenayan kakafin i enan. I aurin fair men ema’am ayu nisnowahu.
31 Ṣùgbọ́n nítorí kí ayé lè mọ̀ pé èmi fẹ́ràn Baba; gẹ́gẹ́ bí Baba sì ti fi àṣẹ fún mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi ń ṣe.
31 Baise sabuw iti tafaramamaim i hinaso’ob ayu Tamai abiyabow isan imih Tamai abistan eo etatarbaiyunu imaim asisinaf.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar João 14, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.