João 12

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Nítorí náà, nígbà tí àjọ ìrékọjá ku ọjọ́ mẹ́fà, Jesu wá sí Betani, níbi tí Lasaru wà, ẹni tí ó ti kú, tí Jesu jí dìde kúrò nínú òkú.
1 Veya six nasasawar ufunamaim i Tar Nowaten ana veya, Jesu na Bethany tit, Lazarus morobone biyawas i ana bar merar.
2 Wọ́n sì ṣe àsè alẹ́ fún un níbẹ̀. Marta sì ń ṣe ìránṣẹ́, ṣùgbọ́n Lasaru jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn tí ó jókòó níbi tábìlì rẹ̀.
2 Nati’imaim rabirab ana bay hibogaigiwas Jesu bairi aa isan, Martha ibaisih bairi bay hisemor. Lazarus orot afa auman Jesu bairi himarir gem sisibinamaim hima’am.
3 Nígbà náà ni Maria mú òróró ìkunra nadi, òsùwọ̀n lita kan, àìlábùlà, olówó iyebíye, ó sì ń fi kun Jesu ní ẹsẹ̀, ó sì ń fi irun orí rẹ̀ nu ẹsẹ̀ rẹ̀ nù. Ilé sì kún fún òórùn ìkunra náà.
3 Raiy yamurin mamarin wabin nard i ai rourin hibun iroro’on hibai. Nati raiy iroro’on ana baiyan i gagamin na’in, Mary bai na isuwei ra’iy Jesu an rororon ihurufen, naatu aribunamaim safam. Naatu yamurin ana mamarin bar wanawanan etei itakwar.
4 Nígbà náà ni ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Judasi Iskariotu, ọmọ Simoni ẹni tí yóò fi í hàn, wí pé,
4 Baise ana bai’ufununayan orot ta, Judas Iscariot boro ufibo baban nao, i eo,
5 “Èéṣe tí a kò ta òróró ìkunra yìí ní ọ̀ọ́dúnrún owó idẹ kí a sì fi fún àwọn tálákà?”
5 “Ana gewasin iti raiy yamurin mamarin ana baiyan 300 silver coins tatayai sabuw hitatubun naatu kabay tatab bai’akirayah tatibaisih.”
6 Ṣùgbọ́n ó wí èyí, kì í ṣe nítorí tí ó náání àwọn tálákà; ṣùgbọ́n nítorí tí ó jẹ́ olè, òun ni ó ni àpò, a sì máa jí ohun tí a fi sínú rẹ̀ láti fi ran ara rẹ lọ́wọ́.
6 Iti tur eo’o, asir sabuw hinanot i akir sabuw baibaisih isah not eo hinarouw, baise i bainowan orot ta, anayabin hai kabay koukufet kakaif, abistan ekokok i ebai ana kokomaim esisinaf.
7 Nígbà náà ni Jesu wí pé, “Ẹ fi í sílẹ̀, ó ṣe é sílẹ̀ de ọjọ́ ìsìnkú mi.
7 Jesu iya’afut eo, “Babin kwaihamiy! Abistan biyanamaim ema’am i ayu anamorob hinayaya’u isan eyayabuna.
8 Nígbà gbogbo ni ẹ̀yin sá à ní tálákà pẹ̀lú yín; ṣùgbọ́n èmi ni ẹ kò ní nígbà gbogbo.”
8 Kwa boro mar etei akir sabuw wanawanahimaim kwanama, baise ayu boro men mar etei kwa bairit tanama’amih.”
9 Nítorí náà, ìjọ ènìyàn nínú àwọn Júù ni ó mọ̀ pé ó wà níbẹ̀; wọ́n sì wá, kì í ṣe nítorí Jesu nìkan, ṣùgbọ́n kí wọn lè rí Lasaru pẹ̀lú, ẹni tí ó ti jí dìde kúrò nínú òkú.
9 Sabuw moumurin maiyow tur hinowar Jesu i na Bethany ma’am, imih sabuw Jesu itinamih hin, men i akisin itinamih hin baise Lazarus morobone Jesu biyawas auman itinamih hin.
10 Ṣùgbọ́n àwọn olórí àlùfáà gbìmọ̀ kí wọn lè pa Lasaru pẹ̀lú,
10 Imih firis gagamih ef hinuwet hiyakitifuw Lazarus auman hitarab tamorob isan.
11 nítorí pé nípasẹ̀ rẹ̀ ni ọ̀pọ̀ nínú àwọn Júù jáde lọ, wọ́n sì gbà Jesu gbọ́.
11 Anayabin Lazarus biyanamaim abistan matar hi’itin Jew sabuw moumurin maiyow himisir firis gagamih hikwahirih naatu Jesu isan higeger hitumitum.
12 Ní ọjọ́ kejì nígbà tí ọ̀pọ̀ ènìyàn tí ó wá sí àjọ gbọ́ pé, Jesu ń bọ̀ wá sí Jerusalẹmu.
12 Marto sabuw rou’ay gagamin maiyow hiru’ay Tar Nowaten ana Hiyuw isan, tur hinowar Jesu i enan au Jerusalem.
13 Wọ́n mú imọ̀ ọ̀pẹ, wọ́n sì jáde lọ pàdé rẹ̀, wọ́n sì ń kígbe pé,
13 Sabuw ai rourih hikakir naatu hitit hin Jesu nan bairi baitaramih, hitarkoukuw hi’o, “God tanifai! Regah wabinamaim enan, God nigegewasin! Israel hai aiwob inigegewasin!” Hitit hin bairi hitar.
14 Nígbà tí Jesu sì rí ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan, ó gùn ún; gẹ́gẹ́ bí a ti kọ̀wé pé,
14 Bobaituw boubun wabin donkey hitita’ur naatu afe’enamaim mara’at ma remor yen in. Buk Atamaninamaim hikirum hi’o na’atube.
15 “Má bẹ̀rù, ọmọbìnrin Sioni;
15 “O Zion Natun Babitai, Men inabir;
16 Nǹkan wọ̀nyí kò tètè yé àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ṣùgbọ́n nígbà tí a ṣe Jesu lógo, nígbà náà ni wọ́n rántí pé, a kọ̀wé nǹkan wọ̀nyí nípa rẹ̀ sí i.
16 Abistan nati ana veya himamatar ana bai’ufununayah men hiso’ob. Baise Jesu ana fair nabaib ufunamaim, imaibo hina’itin hinaso’ob. Buk Atamaninamaim i isan hi’o hikirum, naatu hisinafen himatar.
17 Nítorí náà, ìjọ ènìyàn tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ nígbà tí o pé Lasaru jáde nínú ibojì rẹ̀, tí ó sì jí i dìde kúrò nínú òkú, jẹ́rìí sí i.
17 Sabuw iyab Jesu bairi hin rahemaim hitit Lazarus morobone yawas misir hi’i’itin hi’o tur ra’at tasasar.
18 Nítorí èyí ni ìjọ ènìyàn sì ṣe lọ pàdé rẹ̀, nítorí tí wọ́n gbọ́ pé ó ti ṣe iṣẹ́ àmì yìí.
18 Sabuw moumurin maiyow hitit hin Jesu biyan hitit, anayabin tur hinowar i ina’inan iti na’atube men tisinaf emamatar i sinaf matar.
19 Nítorí náà àwọn Farisi wí fún ara wọn pé, “Ẹ kíyèsi bí ẹ kò ti lè borí ní ohunkóhun? Ẹ wo bí gbogbo ayé ti ń wọ́ tọ̀ ọ́!”
19 Imih Pharisee taiyuwih himare hi’o, “It abistan tayayakitifuw men kafa’imo emamatar. Sabuw etei i’etaw tebi’ufunun kwa’i’itin!”
20 Àwọn Giriki kan sì wà nínú àwọn tí ó gòkè wá láti sìn nígbà àjọ,
20 Greek sabuw afa wanawanahimaim bairi hiyen hin Jerusalem hiyuw ana veya imaim kwafirin isan.
21 Àwọn wọ̀nyí ni ó tọ Filipi wá, ẹni tí í ṣe ará Betisaida tí Galili, wọ́n sì ń béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, pé, “Alàgbà, àwa ń fẹ́ rí Jesu!”
21 Hina Philip biyan hitit, i Betsaida orot Galilee wanawanan, isan hifefeyan hi’o, “Aro, aki akokok Jesu ana’itin.”
22 Filipi wá, ó sì sọ fún Anderu; Anderu àti Filipi wá, wọ́n sì sọ fún Jesu.
22 Philip in Andrew ana tur eowen, naatu Andrew Philip hairi hin Jesu ana tur hi’owen.
23 Jesu sì dá wọn lóhùn pé, “Wákàtí náà dé, tí a ó ṣe Ọmọ Ènìyàn lógo.
23 Jesu iyafutih eo, “Orot Natun baifa’in naatu bora’ara’ahin isan ana veya na kabom.
24 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, bí kò ṣe pé alikama bá bọ́ sí ilẹ̀, tí ó bá sì kú, ó wà ní òun nìkan; ṣùgbọ́n bí ó bá kú, yóò sì so ọ̀pọ̀lọpọ̀ èso.
24 Ayu turobe a tur ao’owen, sanabey tutufin ta’imon hinama’ub me yan hinataun na’inu’in, naatu nabikubobun boro moumurih na’in hinayen naatu ani’anin boro moumurih na’in naya.
25 Ẹni tí ó bá fẹ́ ẹ̀mí rẹ̀ yóò sọ ọ́ nù; ẹni tí ó bá sì kórìíra ẹ̀mí rẹ̀ láyé yìí ni yóò sì pa á mọ́ títí ó fi di ìyè àìnípẹ̀kun.
25 Orot yait taiyuwin ana yawas ebiyabuw i boro yawas narusa’ir, naatu yait iti tafaramamaim taiyuwin ana yawas ekwakwahir boro nabotan yawas wanatowan isan.”
26 Bí ẹnikẹ́ni bá ń sìn mí, kí ó máa tọ̀ mí lẹ́yìn, àti pe níbi tí èmi bá wà, níbẹ̀ ni ìránṣẹ́ mi yóò wà pẹ̀lú, bí ẹnikẹ́ni bá ń sìn mí, òun ni Baba yóò bu ọlá fún.
26 Yait ayu isou nabowabow, i ayu ni’ufnunu, naatu ayu menamaim ama’am au akir orot boro airi imaim anama. Yait ayu isou ebowabow Tamai boro nifai nabora’ara’ah.
27 “Ní ìsinsin yìí ni a ń pọ́n ọkàn mi lójú; kín ni èmi ó sì wí? ‘Baba, gbà mí kúrò nínú wákàtí yìí’? Rárá, ṣùgbọ́n nítorí èyí ni mo ṣe wá sí wákàtí yìí.
27 “Ayu dogorou i yababan awan karatan, Tamai ayu boro mi’itube anao? Iti bai’akir ana veya iniyawasu? ‘Aiyabin, Tamai iti bai’akir ana veya nan anabaib isan ana atit.
28 Baba, ṣe orúkọ rẹ lógo!”
28 Tamai o wab anabora’ah.” Naatu marane fanan tit eo, “Ayu wab abora’ahika naatu boro anabora’ah maiye.’”
29 Nítorí náà ìjọ ènìyàn tí ó dúró níbẹ̀, tí wọ́n sì gbọ́ ọ, wí pé, “Àrá ń sán.” Àwọn ẹlòmíràn wí pé, “Angẹli kan ni ó ń bá a sọ̀rọ̀.”
29 Sabuw rou’ay nati’imaim hibatabat hinowar, afa hi’o, gunum rab naatu afa hi’o, “Tounamatar isan eo.”
30 Jesu sì dáhùn wí pé, “Kì í ṣe nítorí mi ni ohùn yìí ṣe wá, bí kò ṣe nítorí yín.
30 Jesu eo, “Iti fanan i kwa isa eo, men ayu isou.
31 Ní ìsinsin yìí ni ìdájọ́ ayé yìí dé: nísinsin yìí ni a ó lé aládé ayé yìí jáde.
31 Veya boun iti tafaram baibabatiyin isan naatu iti tafaram ana aiwob boun boro hinabosair.
32 Àti èmi, bí a bá gbé mi sókè kúrò ní ayé, èmi ó fa gbogbo ènìyàn sọ́dọ̀ ara mi!”
32 Baise Ayu iti tafaramamaim hinabobora’ahu anamaramaim, sabuw etei boro anabonawiyih hinan ayu akisu biyou hinatit.”
33 Ṣùgbọ́n ó wí èyí, ó ń ṣe àpẹẹrẹ irú ikú tí òun yóò kú.
33 Iti tur eo, i mi’itube ti’obaiyih i ana morob ana itinin boro mi’itube namorob.
34 Nítorí náà àwọn ìjọ ènìyàn dá a lóhùn pé, “Àwa gbọ́ nínú òfin pé, Kristi wà títí láéláé, ìwọ ha ṣe wí pé, ‘A ó gbé Ọmọ Ènìyàn sókè’? Ta ni ó ń jẹ́ ‘Ọmọ Ènìyàn yìí’?”
34 Sabuw hi’o, “Aki ofafaramaim anonowar Keriso boro nama wanatowan, naatu o mi’itube ku’o’o, Orot Natun boro hinabora’ah. Iti Orot Natunam yait?”
35 Nígbà náà ni Jesu wí fún wọn pé, “Nígbà díẹ̀ sí i ni ìmọ́lẹ̀ wà láàrín yín, ẹ máa rìn nígbà tí ẹ̀yin ní ìmọ́lẹ̀, kí òkùnkùn má ṣe bá yín, ẹni tí ó bá sì ń rìn ní òkùnkùn kò mọ ibi òun ń lọ.
35 Naatu Jesu uwih eo, “Kwa mar kafai boro marakaw kwanab, marakaw kwabaibimaim kwanaremor, imaibo gugumin nan natarsumi. Orot yait guguminamaim ereremor i men so’ob menamaim enan.
36 Nígbà tí ẹ̀yin ní ìmọ́lẹ̀, ẹ gba ìmọ́lẹ̀ gbọ́, kí ẹ lè jẹ́ ọmọ ìmọ́lẹ̀!” Nǹkan wọ̀nyí ni Jesu sọ, ó sì jáde lọ, ó fi ara pamọ́ fún wọn.
36 Marakaw nati kwabai kwama’am a baitumatum i kwanitin. Saise kwa boro kwanan marakaw natunatun kwanamatar.” Iti eo’o ufunamaim, Jesu sabuw ihamiyih naatu i taiyuwin ibunwa’ir.
37 Ṣùgbọ́n bí ó ti ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì tó báyìí lójú wọn, wọn kò gbà á gbọ́.
37 Mensanet Jesu wanawanahimaim sawar faifirih imamataren, baise i boro’ika men tibitumitum.
38 Kí ọ̀rọ̀ wòlíì Isaiah lè ṣẹ, èyí tí ó sọ pé,
38 Iti i mi’itube dinab orot Isaiah ana tur eo’o i titurobe isan. “Regah, yait aki tur a’o ebitumitum? Yait biyanamaim Regah ana fair ebirerereb?”
39 Nítorí èyí ni wọn kò fi lè gbàgbọ́, nítorí Isaiah sì tún sọ pé,
39 Anayabin iti isan, men karam hititumatum, imih Isaiah eo maiye;
40 “Ó ti fọ́ wọn lójú,
40 “God iwa’an matah hifim
41 Nǹkan wọ̀nyí ni Isaiah wí, nítorí ó ti rí ògo rẹ̀, ó sì sọ̀rọ̀ rẹ̀.
41 Isaiah iti eo’o, anayabin Jesu ana marakaw itin naatu isan eo i nowar.
42 Síbẹ̀ ọ̀pọ̀ nínú àwọn olórí gbà á gbọ́ pẹ̀lú; ṣùgbọ́n nítorí àwọn Farisi wọn kò jẹ́wọ́ rẹ̀, kí a má ba à yọ wọ́n kúrò nínú Sinagọgu,
42 Naatu nati veya ta’imon wanawanan Jew ukwa’ukwarih wanawanahimaim Jesu hitumitum. Baise anayabin Pharisee isah hibir, men karam hai baitumatum hitao rereb, i boro kou’ay barene hitabotaitih.
43 nítorí wọ́n fẹ́ ìyìn ènìyàn ju ìyìn ti Ọlọ́run lọ.
43 Anayabin i orot babin isah tibiyabow men boun God isan tebiyabow na’atube.
44 Jesu sì kígbe ó sì wí pé, “Ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́, èmi kọ́ ni ó gbàgbọ́ ṣùgbọ́n ẹni tí ó rán mi.
44 Basit Jesu fanan aumetawat eo, “Orot ayu ebitutumu, i men ayu akisu ebitutumu, baise yait ayu iyafaru anan auman ebitumitum.
45 Ẹni tí ó bá sì rí mi, ó rí ẹni tí ó rán mi.
45 Yait ayu i’itu anamaramaim, ayu iyafaru anan auman i’itin.
46 Èmi ni ìmọ́lẹ̀ tí ó wá sí ayé, kí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà mí gbọ́ má ṣe wà nínú òkùnkùn.
46 Ayu i marakaw na’atube ana tafaramamaim atit, saise yait ayu ebitutumu i boro men guguminamaim nama.
47 “Bí ẹnikẹ́ni bá sì gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, tí kò sì pa wọ́n mọ́, èmi kì yóò ṣe ìdájọ́ rẹ̀ nítorí tí èmi kò wá láti ṣe ìdájọ́ ayé, bí kò ṣe láti gba ayé là.
47 Orot yait ayu au tur enonowar baise men ebaib, ayu boro men anibatiy. Ayu men tafaram fufuninamih ana atit, baise baiyawasinamih ana.
48 Ẹni tí ó bá kọ̀ mí, tí kò sì gba ọ̀rọ̀ mi, ó ní ẹnìkan tí ń ṣe ìdájọ́ rẹ̀; ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ, òun náà ni yóò ṣe ìdájọ́ rẹ̀ ní ọjọ́ ìkẹyìn.
48 Yait ayu ebifutuwu naatu au tur men ebaib i ana baibatiyenayan ema’am. Tur iti ayu a’o i boro mar yomaninamaim nibabatiyi.
49 Nítorí èmi kò dá ọ̀rọ̀ sọ fún ara mi, ṣùgbọ́n Baba tí ó rán mi, ni ó ti fún mi ní àṣẹ, ohun tí èmi ó sọ, àti èyí tí èmi ó wí.
49 Anayabin ayu men taiyuwu au kokomaim ao’omih, baise Tamai ayu iyafaru anan tarbaiyunu tur abistanawat anao naatu boro mi’itube ana’o.
50 Èmi sì mọ̀ pé ìyè àìnípẹ̀kun ni òfin rẹ̀, nítorí náà, àwọn ohun tí mo bá wí, gẹ́gẹ́ bí Baba ti sọ fún mi, bẹ́ẹ̀ ni mo wí!”
50 Naatu ayu aso’ob i ana tarbaiyunen tur boro nabonawiy inan ma’ama wanatowan. Imih ayu abistan ao’o i mutufor, Tamai uwu imih ao’o.”

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar João 12, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.