João 10
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 “Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ẹni tí kò bá gba ẹnu-ọ̀nà wọ inú agbo àgùntàn, ṣùgbọ́n tí ó bá gba ibòmíràn gun òkè, òun náà ni olè àti ọlọ́ṣà.
1 “Turobe a tur ao’owen, bobaituw hai fur ana etawanamaim orot men imaim narun, baise nakayam ef ta’ane narun, nati orot i bainowan mowan.
2 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá ti ẹnu-ọ̀nà wọlé, Òun ni olùṣọ́ àwọn àgùntàn.
2 Orot yait etawanamaim erur, i bobaituw kaifenayan.
3 Òun ni aṣọ́nà yóò ṣílẹ̀kùn fún; àwọn àgùntàn gbọ́ ohùn rẹ̀, ó sì pe àwọn àgùntàn tirẹ̀ lórúkọ, ó sì ṣe amọ̀nà wọn jáde.
3 Orot fur kaifenayan boro etawan isan nabotawiy naatu bobaituw boro orot fanan hina’inan naatu ana bobaituw ta’ita’imon wabih naso’oben na’afih hinanowar naatu nabotaitih ufun hinatit.
4 Nígbà tí ó bá sì ti mú àwọn àgùntàn tirẹ̀ jáde, yóò síwájú wọn, àwọn àgùntàn yóò sì máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, nítorí tí wọ́n mọ ohùn rẹ̀.
4 I ebotaitih ufun tetitit anamaramaim, i wan ebi’iyon, naatu ana bobaituw ti’ufunun bairi tenan anayabin i fanan hiso’ob.
5 Wọn kò jẹ́ tọ àlejò lẹ́yìn, ṣùgbọ́n wọn a sá kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí tí wọn kò mọ ohùn àlejò.”
5 Baise fanan ta boro men hini’ufunun, anayabin i fanan men hi’inan imih boro hinabihir.”
6 Òwe yìí ni Jesu pa fún wọn, ṣùgbọ́n òye ohun tí nǹkan wọ̀nyí tí ó ń sọ fún wọn kò yé wọn.
6 Jesu iti kawen turamaim eo, baise tur ana naniyan i men hibaimih abistan isan eo’o.
7 Nítorí náà Jesu tún wí fún wọn pé, “Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, Èmi ni ìlẹ̀kùn àwọn àgùntàn.
7 Imih Jesu tur ibanak eo maiye, “Turobe a tur ao’owen, Ayu i etawan bobaituw isah.
8 Olè àti ọlọ́ṣà ni gbogbo àwọn tí ó ti wà ṣáájú mi, ṣùgbọ́n àwọn àgùntàn kò gbọ́ tiwọn.
8 Sabuw afa wan hinan i bainowah naatu bokwanekwaneyah, baise bobaituw men tainih isah hirub fanah hinowaramih.
9 Èmi ni ìlẹ̀kùn, bí ẹnìkan bá bá ọ̀dọ̀ mi wọlé, òun ni a ó gbàlà, yóò wọlé, yóò sì jáde, yóò sì rí koríko.
9 Ayu i etawan, yait ayu wanawana’umaim run enan boro yawas nab, boro hinarun hinatit fotan gewasin hinagatur.
10 Olè kì í wá bí kò ṣe láti jalè, láti pa, àti láti parun; èmi wá kí wọn lè ní ìyè, àní kí wọn lè ní i lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
10 Bainowan tenan i bain, asbunin naatu gurusin akisin hinot tenan; Ayu anan i boro yawas gewasin hinab hinama boro men abistan ta isan hiniyababan.”
11 “Èmi ni olùṣọ́-àgùntàn rere, olùṣọ́-àgùntàn rere fi ọkàn rẹ̀ lélẹ̀ nítorí àwọn àgùntàn.
11 “Ayu i bobaituw gewasu. Bobaituw Kaifenayan gewasin ana bobaituw isah ana yawas ebi’inuw.
12 Ṣùgbọ́n alágbàṣe, tí kì í ṣe olùṣọ́-àgùntàn, ẹni tí àwọn àgùntàn kì í ṣe tirẹ̀, ó rí ìkookò ń bọ̀, ó sì fi àgùntàn sílẹ̀, ó sì fọ́n wọn ká kiri.
12 Bobaituw kaifenayan orot ta men karam bobaituw nakaifen naatu i men nowan. Imih anamaramaim haru tuwetuwenih nan na’i’itin, i boro bobaituw nihamiyih nabihir. Naatu haru tuwenituwenih boro bobaituw bairi hiniyow naatu hina’abargiyih nanabin hinabihir.
13 Òun sálọ nítorí tí ó jẹ́ alágbàṣe, kò sì náání àwọn àgùntàn.
13 Orot boro nabihir anayabin i orot ta hibai na ma ekakaifen, imih bobaituw isah i men enotanot gagamin.
14 “Èmi ni olùṣọ́-àgùntàn rere, mo sì mọ àwọn tèmi, àwọn tèmi sì mọ̀ mí.
14 Ayu i bobaituw kaifenayan gewasu. Au bobaituw asu’ubih naatu i ayu hisu’ubu.
15 Gẹ́gẹ́ bí Baba ti mọ̀ mí, tí èmi sì mọ Baba, mo sì fi ọkàn mi lélẹ̀ nítorí àwọn àgùntàn.
15 Tamai ayu susu’ubu na’atube, ayu Tamai asu’ub naatu au yawas bobaituw isah ai’inuw.
16 Èmi sì ní àwọn àgùntàn mìíràn, tí kì í ṣe agbo yìí: àwọn ni èmi yóò mú wá pẹ̀lú, wọn yóò sì gbọ́ ohùn mi; wọn ó sì jẹ́ agbo kan, olùṣọ́-àgùntàn kan.
16 Bobaituw afa ayu nowau i men iti fur wanawanan tema’am. I auman anabuwih hinan hinarun. I auman ayu fanau hinanowar, nati’imaim i boro bobaituw ta’imon naatu kaifenayan ta’imon.
17 Nítorí náà ni Baba mi ṣe fẹ́ràn mi, nítorí tí mo fi ẹ̀mí mi lélẹ̀, kí èmi lè tún gbà á.
17 Tamai ebiyabuwu anayabin ayu au yawas ani’inuw, saise yawasu anama maiye.
18 Ẹnìkan kò gbà á lọ́wọ́ mi, ṣùgbọ́n mo fi í lélẹ̀, mo sì lágbára láti tún gbà á. Àṣẹ yìí ni mo ti gbà wá láti ọ̀dọ̀ Baba mi.”
18 Men yait ta ayu au yawas nabosair, baise ayu taiyuwu au kokomaim au yawas anayara’iy. Ayu au fair ema’am anayara’iy naatu au fair ema’am anabora’ah maiye. Iti obaiyunen i Tamai biyanane abai.”
19 Nítorí náà ìyapa tún wà láàrín àwọn Júù nítorí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí.
19 Iti tur hinonowar anamaramaim Jew sabuw tarsibih maiye.
20 Ọ̀pọ̀ nínú wọn sì wí pé, “Ó ní ẹ̀mí èṣù, orí rẹ̀ sì dàrú; èéṣe tí ẹ̀yin fi ń gbọ́rọ̀ rẹ̀?”
20 Sabuw moumurih maiyow hi’o, “I demon hitounbubur ema’am naatu ebikoko’aw. Aisim ana tur kwanonowar.”
21 Àwọn mìíràn wí pé, “Ìwọ̀nyí kì í ṣe ọ̀rọ̀ ẹni tí ó ní ẹ̀mí èṣù. Ẹ̀mí èṣù lè la ojú àwọn afọ́jú bí?”
21 Baise sabuw afa hi’o, “Tur iti na’atube men karam orot demon hinatounbubur ema’am nao’omih. Mi’itube demon orot matan fim nabotawiy?
22 Àkókò náà sì jẹ́ àjọ̀dún ìyàsímímọ́ ní Jerusalẹmu, ni ìgbà òtútù.
22 Nati rarabkokou wanawanan Tafaror Bar ana hiyuw wabin Koksouwen i Jerusalemamaim hibogaigiwas.
23 Jesu sì ń rìn ní tẹmpili, ní ìloro Solomoni.
23 Naatu Jesu Solomon ana efan awan ta Tafaror Bar wanawanan imaim bat reremor.
24 Nítorí náà àwọn Júù wá dúró yí i ká, wọ́n sì wí fún un pé, “Ìwọ ó ti mú wa ṣe iyèméjì pẹ́ tó? Bí ìwọ bá ni Kristi náà, wí fún wa gbangba.”
24 Jew hai ukwarih hiru’ay hi’arbebera’uh hi’u, “Mar bai’ab boro inabotani anama anakaifi? O Keriso na’at, bebeyanamaim ku’o anowar.”
25 Jesu dá wọn lóhùn pé, “Èmi ti wí fún yín, ẹ̀yin kò sì gbàgbọ́; iṣẹ́ tí èmi ń ṣe lórúkọ Baba mi, àwọn ni ó ń jẹ́rìí mi.
25 Jesu iyafutih eo, “Ayu kwa a tur aowen, baise kwa men kwaitumatum. Ina’inanen ayu Tamai wabinamaim asisinaf i ayu isou eo’orereb.
26 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbàgbọ́, nítorí ẹ̀yin kò sí nínú àwọn àgùntàn mi, gẹ́gẹ́ bí mo tí wí fún yín.
26 Baise kwa men kwabitumatum anayabin kwa men ayu au bobaituw.
27 Àwọn àgùntàn mi ń gbọ́ ohùn mi, èmi sì mọ̀ wọ́n, wọn a sì máa tọ̀ mí lẹ́yìn.
27 Ayu au bobaituw asu’ubih imih fanau hinowar tebi’ufnunu.
28 Èmi sì fún wọn ní ìyè àìnípẹ̀kun; wọn kì yóò sì ṣègbé láéláé, kò sí ẹni tí ó lè já wọn gbà kúrò lọ́wọ́ mi.
28 Ayu yawas wanatowan abitih; naatu boro men ta nakasiy; men ta ayu umou’umaim nabosair.
29 Baba mi, ẹni tí ó fi wọ́n fún mi pọ̀ ju gbogbo wọn lọ; kò sì ṣí ẹni tí ó lè já wọn gbà kúrò lọ́wọ́ Baba mi.
29 Tamai ayu bow bitu i ra’at etei natabirih, imih ayu Tamai umanamaim men yait ta nabosairen.
30 Ọ̀kan ni èmi àti Baba mi.”
30 Tamai naatu Ayu airi i ta’imon.
31 Àwọn Júù sì tún mú òkúta, láti sọ lù ú.
31 Ibanak maiye Jew sabuw kabay hibow hitarabimih,
32 Jesu dá wọn lóhùn pé, “Ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ rere ni mo fihàn yín láti ọ̀dọ̀ Baba mi wá, nítorí èwo nínú iṣẹ́ wọ̀nyí ni ẹ̀yin ṣe sọ mí ní òkúta?”
32 baise Jesu sabuw isah eo, “Ayu Tamai biyanane ina’inan gagamih moumurih maiyow ai’obaiyi. Anayabin iti isan ayu kabayamaim kwanarabu.”
33 Àwọn Júù sì dá a lóhùn pé, “Àwa kò sọ ọ́ lókùúta nítorí iṣẹ́ rere, ṣùgbọ́n nítorí ọ̀rọ̀-òdì, àti nítorí ìwọ tí í ṣe ènìyàn ń fi ara rẹ pe Ọlọ́run.”
33 Jew hiya’afut hi’o, “Aki men nati isan kabayamaim anarabi, baise o God kubi’i’iyab, anayabin o i orot maiyow, naatu taiyuw God kurarouw.”
34 Jesu dá wọn lóhùn pé, “A kò ha tí kọ ọ́ nínú òfin yín pé, ‘Mo ti wí pé, Ọlọ́run ni ẹ̀yin jẹ́’?
34 Jesu iyafutih eo, “Kwa a Buk Atamaninamaim iti na’atube hikirum ema’am, ayu ao’o kwa etei i god?
35 Bí ó bá pè wọ́n ní ‘ọlọ́run,’ àwọn ẹni tí a fi ọ̀rọ̀ Ọlọ́run fún, a kò sì lè ba ìwé mímọ́ jẹ́.
35 I etei god narouw na’a’afih na’at, tur God i menane na naatu Buk Atamaninamaim hikikirum men hina’astu’ub.
36 Kín ni ẹyin ha ń wí ní ti ẹni tí Baba yà sọ́tọ̀, tí ó sì rán sí ayé kín lo de ti ẹ fi ẹ̀sùn kàn mi pé mò ń sọ̀rọ̀-òdì nítorí pé mo sọ pé, ‘Èmi ni Ọmọ Ọlọ́run.’
36 Ayu Tamai yasairu i nowanamih amatar naatu irubinu naatu iyafaru ana iti tafaramaim atitit i boro mi’itube? Mi’itube ayu God bai’i’iyabin kwarouw kwa’o’o, anayabin ayu God Natun arouw ao’omih?
37 Bí èmi kò bá ṣe iṣẹ́ Baba mi, ẹ má ṣe gbà mí gbọ́.
37 Ayu Tamai sisinafube men ana sisinaf bibaitutumu.
38 Ṣùgbọ́n bí èmi bá ṣe wọ́n, bí ẹ̀yin kò tilẹ̀ gbà mí gbọ́, ẹ gbà iṣẹ́ náà gbọ́, kí ẹ̀yin ba à lè mọ̀, kí ó sì lè yé yín pé, Baba wà nínú mi, èmi sì wà nínú rẹ̀.”
38 Baise ayu ata sinaf kwa men kwatabitutumu na’at, karam nati ina’inanen kwata’itah kwataso’ob imaim kwatitumatum, ayu i Tamai wanawanan, naatu Tamai i ayu wanawanau.”
39 Wọ́n sì tún ń wá ọ̀nà láti mú un: ó sì bọ́ lọ́wọ́ wọn.
39 Ibanak maiye bain rabinamih hiwa’an, baise i umahine soratait tit.
40 Ó sì tún kọjá lọ sí apá kejì Jordani sí ibi tí Johanu ti kọ́kọ́ ń bamitiisi; níbẹ̀ ni ó sì jókòó.
40 Naatu Jesu ibanak matabir maiye Jordan rabon rounane, marasika John sabuw imaim bapataito bitih efan imaim tit naatu Jesu imaim ma.
41 Àwọn ènìyàn púpọ̀ sì wá sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n sì wí pé, “Johanu kò ṣe iṣẹ́ àmì kan, Ṣùgbọ́n òtítọ́ ni ohun gbogbo tí Johanu sọ nípa ti ọkùnrin yìí.”
41 Naatu sabuw moumurin maiyow hina biyan hitit, naatu hi’o, “John ina’inan men ta sinaf a’itin, baise John iti orot isan eo’o i turobe.”
42 Àwọn ènìyàn púpọ̀ níbẹ̀ sì gbà á gbọ́.
42 Efan nati’imaim sabuw moumurin maiyow Jesu hitumitum.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar João 10, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.