Isaías 7
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Nígbà tí Ahasi ọmọ Jotamu ọmọ Ussiah jẹ́ ọba Juda, ọba Resini ti Aramu àti Peka ọmọ Remaliah ọba Israẹli gòkè wá láti bá Jerusalẹmu jà, ṣùgbọ́n wọn kò sì le è borí i rẹ̀.
1 E aconteceu nos dias de Acaz, o filho de Jotão, o filho de Uzias, rei de Judá, que Rezim, o rei da Síria, e Peca, o filho de Remalias, o rei de Israel, subiu em direção a Jerusalém para guerrear contra ela, mas não pôde prevalecer contra ela.
2 Báyìí, a sọ fún ilé Dafidi pé, “Aramu mà ti lẹ̀dí àpò pọ̀ mọ́ Efraimu”; fún ìdí èyí, ọkàn Ahasi àti àwọn ènìyàn rẹ̀ wárìrì gẹ́gẹ́ bí igi oko ṣe ń wárìrì níwájú afẹ́fẹ́.
2 E isto foi dito à casa de Davi, dizendo: A Síria está confederada com Efraim. E o coração dele foi abalado e o coração de seu povo, da mesma forma que as árvores da floresta são agitadas pelo vento.
3 Lẹ́yìn èyí, Olúwa sọ fún Isaiah pé, “Jáde, ìwọ àti ọ̀dọ́mọkùnrin rẹ Ṣeari-Jaṣubu láti pàdé Ahasi ní ìpẹ̀kun ìṣàn omi ti adágún òkè, ní òpópó ọ̀nà tí ó lọ sí pápá Alágbàfọ̀.
3 Então disse o SENHOR a Isaías: Saia agora para encontrar Acaz, tu e teu filho Sear-Jasube, no final do aqueduto do reservatório superior, na estrada do campo do lavandeiro.
4 Sọ fún un, ‘Ṣọ́ra à rẹ, fi ọkàn balẹ̀, kí o má ṣe bẹ̀rù. Má ṣe ba ọkàn jẹ́ nítorí kùkùté igi ìdáná méjèèjì yìí, nítorí ìbínú gbígbóná Resini àti Aramu àti ti ọmọ Remaliah.
4 Dize-lhe: Fique atento, e fique quieto; não tenha medo, nem se desanime pelos dois pedaços de tições fumegantes, pela feroz ira de Rezim com a Síria, e do filho de Remalias.
5 Aramu, Efraimu àti Remaliah ti dìtẹ̀ ìparun rẹ, wọ́n wí pé,
5 Porque a Síria, Efraim e o filho de Remalias têm formado um maligno conselho contra ti, dizendo:
6 “Jẹ́ kí a kọlu Juda; jẹ́ kí a fà á ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, kí a sì pín in láàrín ara wa, kí a sì fi ọmọ Tabeli jẹ ọba lórí i rẹ̀.”
6 Deixe-nos subir contra Judá e afligi-la, deixe-nos fazer uma brecha naquele lugar para nós e colocar um rei no meio dele, precisamente, o filho de Tabeal.
7 Síbẹ̀ èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí:
7 Portanto, diz o Senhor DEUS: Isto não irá prevalecer, nem acontecerá.
8 nítorí Damasku ni orí Aramu,
8 Porque a cabeça da Síria é Damasco e a cabeça de Damasco é Rezim; e dentro de sessenta e cinco anos Efraim será quebrado, de tal forma que não será um povo.
9 Orí Efraimu sì ni Samaria,
9 E a cabeça de Efraim é Samaria e a cabeça de Samaria é filho de Remalias. Se vós não crerdes, certamente não sereis estabelecidos.
10 Bákan náà Olúwa tún bá Ahasi sọ̀rọ̀,
10 Além disso, o SENHOR falou novamente a Acaz, dizendo:
11 “Béèrè fún àmì lọ́wọ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ, bóyá ní ọ̀gbun tí ó jì jùlọ tàbí àwọn òkè tí ó ga jùlọ.”
11 Pede um sinal ao SENHOR teu Deus. Pede-o, seja nas profundezas ou nas alturas.
12 Ṣùgbọ́n Ahasi sọ pé, “Èmi kì yóò béèrè; Èmi kò ní dán Olúwa wò.”
12 Porém, Acaz disse: Eu não pedirei, nem tentarei o SENHOR.
13 Lẹ́yìn náà Isaiah sọ pé, “Gbọ́ ní ìsinsin yìí, ìwọ ilé Dafidi, kò ha tọ́ láti tán ènìyàn ní sùúrù, ìwọ yóò ha tan Ọlọ́run ní sùúrù bí?
13 E ele disse: Ouvi vós agora, ó casa de Davi: É isto pouca coisa para vós enfadardes homens, porém ireis vós enfadar meu Deus também?
14 Nítorí náà, Olúwa fúnra ara rẹ̀ ni yóò fún ọ ní àmì kan. Wúńdíá kan yóò lóyún, yóò sì bí ọmọkùnrin kan, yóò sì pe orúkọ rẹ̀ ní Emmanueli.
14 Portanto, o Senhor mesmo vos dará um sinal: Eis que, uma virgem conceberá e dará à luz um filho e chamará seu nome Emanuel.
15 Òun yóò jẹ wàrà àti oyin nígbà tí ó bá ní ìmọ̀ tó láti kọ ẹ̀bi àti láti yan rere.
15 Ele comerá manteiga e mel, para que possa saber rejeitar o mal e escolher o bem.
16 Ṣùgbọ́n kí ọ̀dọ́mọkùnrin náà tó mọ bí a ti ń kọ ẹ̀bi àti láti yan rere, ilẹ̀ àwọn ọba méjèèjì tí ń bà ọ́ lẹ́rù wọ̀nyí yóò ti di ahoro.
16 Porque, antes que a criança saiba rejeitar o mal e escolher o bem, a terra que tu detestas será abandonada de ambos os seus reis.
17 Olúwa yóò mú àsìkò mìíràn wá fún ọ àti àwọn ènìyàn rẹ àti lórí ilé baba rẹ irú èyí tí kò sí láti ìgbà tí Efraimu ti yà kúrò ní Juda, yóò sì mú ọba Asiria wá.”
17 O SENHOR trará sobre ti, sobre o teu povo, e sobre a casa de teu pai, dias que ainda não têm acontecido desde o dia em que Efraim afastou-se de Judá, o rei da Assíria.
18 Ní ọjọ́ náà ni Olúwa yóò súfèé pe àwọn eṣinṣin láti àwọn odò tó jìnnà ní Ejibiti wá, àti fún àwọn oyin láti ilẹ̀ Asiria.
18 E acontecerá naquele dia que o SENHOR assobiará para a mosca que está na parte mais extrema dos rios do Egito, e para a abelha que está na terra da Assíria.
19 Gbogbo wọn yóò sì wá dó sí gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè àti pàlàpálá òkúta, lára koríko ẹ̀gún àti gbogbo ibi ihò omi.
19 E eles virão, e descansarão todos nos vales desolados, no interior de cavidades das rochas, e sobre todos os espinheiros e sobre todos os arbustos.
20 Ní ọjọ́ náà, Olúwa yóò lo abẹ fífẹ́lẹ́ tí a yá láti ìkọjá odò Eufurate, ọba Asiria, láti fá irun orí àti ti àwọn ẹsẹ̀ ẹ yín, àti láti mú irùngbọ̀n yín kúrò pẹ̀lú.
20 No mesmo dia, o Senhor rapará com uma navalha, que é alugada, a saber, por aqueles dalém do rio, pelo rei da Assíria, a cabeça e o pelo dos pés, e isso também consumirá a barba.
21 Ní ọjọ́ náà, ọkùnrin kan yóò máa sin ọ̀dọ́ abo màlúù kan àti ewúrẹ́ méjì.
21 E acontecerá naquele dia, que um homem alimentará uma novilha e duas ovelhas.
22 Àti nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ wàrà tí wọn yóò máa fún un, yóò ní wàràǹkàṣì láti jẹ. Gbogbo àwọn tí ó bá kù ní ilẹ̀ náà yóò jẹ wàràǹkàṣì àti oyin.
22 E acontecerá que, pela abundância de leite que elas produzirão, ele comerá manteiga; porque manteiga e mel comerá cada um que for deixado na terra.
23 Ní ọjọ́ náà, ni gbogbo ibi tí àjàrà tí ó tó ẹgbẹ̀rún (1,000) ṣékélì fàdákà, ẹ̀gún àti ẹ̀wọ̀n nìkan ni yóò wà níbẹ̀.
23 E acontecerá naquele dia, que todo lugar será, onde existiam mil videiras avaliadas em mil moedas de prata, ele será para arbustos com espinhos e espinheiros.
24 Àwọn ènìyàn yóò máa lọ síbẹ̀ pẹ̀lú ọrun àti ọfà nítorí pé ẹ̀gún àti ẹ̀wọ̀n ni yóò bo gbogbo ilẹ̀ náà.
24 Com flechas e com arcos homens irão naquela direção, porque toda a terra tornar-se-á espinhos e espinheiros.
25 Àti ní orí àwọn òkè kéékèèké tí a ti ń fi ọkọ́ ro nígbà kan rí, ẹ kò ní lọ síbẹ̀ mọ́ nítorí ìbẹ̀rù ẹ̀gún àti ẹ̀wọ̀n, wọn yóò di ibi tí a ń da màlúù lọ, àti ibi ìtẹ̀mọ́lẹ̀ fún àwọn àgùntàn kéékèèké.
25 E sobre todas as colinas que serão escavadas com a picareta, não haverá quem vá naquela direção por medo dos espinhos e espinheiros. Porém será para conduzir para lá os bois e para ser pisado pelo gado miúdo.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Isaías 7, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.