Isaías 37

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Nígbà tí ọba Hesekiah gbọ́ èyí, ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì fi aṣọ ọ̀fọ̀ bo ara rẹ̀, ó sì wọ inú tẹmpili Olúwa lọ.
1 E isto aconteceu que, quando o rei Ezequias ouviu isso, ele rasgou suas vestes e cobriu-se com vestimenta de pano de saco, e foi para o interior da casa do SENHOR.
2 Òun sì rán Eliakimu alákòóso ààfin, Ṣebna akọ̀wé, àti aṣíwájú àwọn àlùfáà, gbogbo wọn nínú aṣọ ọ̀fọ̀ lọ sí ọ̀dọ̀ wòlíì Isaiah ọmọ Amosi.
2 E ele enviou Eliaquim, o mordomo, e Sebna, o escrivão, e os anciãos dentre os sacerdotes, cobertos com vestimenta de pano de saco em direção a Isaías, o profeta, o filho de Amós.
3 Wọ́n sọ fún un pé, “Báyìí ni Hesekiah wí, ọjọ́ òní jẹ́ ọjọ́ ìbànújẹ́, ìbáwí àti ẹ̀gàn gẹ́gẹ́ bí ìgbà ìbí àwọn ọmọdé tí kò sì ṣí agbára láti bí wọn.
3 E eles lhe disseram: Desta forma diz Ezequias. Este dia é um dia de dificuldade, e de repreensão, e de blasfêmia, porque as crianças chegam ao momento de nascer e não há força para dar à luz.
4 Ó lè jẹ́ pé Olúwa Ọlọ́run rẹ yóò gbọ́ ọ̀rọ̀ ọ̀gágun ẹni tí ọ̀gá rẹ̀ ọba Asiria ti rán láti fi Ọlọ́run alààyè ṣe ẹlẹ́yà, àti pé òun ni yóò bá a wí nítorí àwọn ọ̀rọ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ ti gbọ́. Nítorí náà gbàdúrà fún àwọn tí ó ṣẹ́kù tí wọ́n sì wà láààyè.”
4 Possivelmente, o SENHOR teu Deus ouvirá as palavras de Rabsaqué, a quem o rei da Assíria, senhor dele, tem enviado para provocar o Deus vivo, e reprovará as palavras que o SENHOR teu Deus tem ouvido. Por conseguinte, ergue tua oração pelo remanescente que é deixado.
5 Nígbà tí àwọn ìjòyè ọba Hesekiah dé ọ̀dọ̀ Isaiah,
5 Então, os servos do rei Ezequias vieram a Isaías.
6 Isaiah sọ fún wọn pé, “Ẹ sọ fún ọ̀gá yín pé, ‘Ohun tí Olúwa sọ nìyìí. Má ṣe bẹ̀rù ohun tí ẹ ti gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ tí ọba Asiria tí ó wà nínú ìdè ti fi sọ̀rọ̀-òdì sí mi.
6 E Isaías disse-lhes: Portanto, vós direis ao vosso senhor. Assim diz o SENHOR: Não tenhas medo das palavras que tu tens ouvido, por meio das quais os servos do rei da Assíria me têm blasfemado.
7 Tẹ́tí sílẹ̀! Èmi yóò fi ẹ̀mí kan sínú rẹ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé bí o bá ti gbọ́ ìròyìn kan, òun yóò padà sí orílẹ̀-èdè rẹ̀, níbẹ̀ ni n ó sì ti jẹ́ kí wọn ké e lulẹ̀ pẹ̀lú idà.’ ”
7 Eis que Eu enviarei um poderoso golpe sobre ele, e ele ouvirá um rumor, e retornará para sua própria terra. E eu o farei cair pela espada em sua própria terra.
8 Nígbà tí ọ̀gágun gbọ́ pé ọba Asiria ti fi Lakiṣi sílẹ̀, ó padà sẹ́yìn, ó sì bá ọba tí ń bá Libina jà.
8 Então, Rabsaqué retornou e encontrou o rei da Assíria guerreando contra Libna, pois ele tinha ouvido que ele havia saído de Láquis.
9 Ní àkókò yìí Sennakeribu gbọ́ ìròyìn kan pé Tirakah ará Kuṣi ọba Ejibiti ń jáde bọ̀ wá bá òun jà. Nígbà tí ó gbọ́ èyí, ó rán oníṣẹ́ sí Hesekiah pẹ̀lú ọ̀rọ̀ wọ̀nyí,
9 E ele ouviu dizer concernente a Tiraca, rei da Etiópia: Ele é vindo para fazer guerra contigo. E quando ele ouviu isto, ele enviou mensageiros a Ezequias, dizendo:
10 “Ẹ sọ fún Hesekiah ọba Juda pé: Má ṣe jẹ́ kí òrìṣà tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé tàn ọ́ jẹ nígbà tí ó sọ pé, ‘A kì yóò jọ̀wọ́ Jerusalẹmu fún ọba Asiria.’
10 Desta forma vós falareis a Ezequias, rei de Judá, dizendo: Não deixes teu Deus, em quem tu confias, enganar-te, dizendo que Jerusalém não será dada na mão do rei da Assíria.
11 Dájúdájú, ìwọ ti gbọ́ ohun tí ọba Asiria ti ṣe sí àwọn orílẹ̀-èdè, tí ó pa wọ́n run pátápátá. Ǹjẹ́ a ó ha dá ọ nídè bí?
11 Eis que tu tens ouvido o que os reis da Assíria têm feito a todas as terras para destruí-las completamente e tu serias livrado?
12 Ǹjẹ́ àwọn òrìṣà àwọn orílẹ̀-èdè tí àwọn baba ńlá mi parun ha gbà wọ́n sílẹ̀ bí àwọn òrìṣà Gosani, Harani, Reṣefu àti àwọn ènìyàn Edeni tí wọ́n wà ní Teli-Assari?
12 Têm os deuses das nações as livrado, as quais meus pais têm destruído, como Gozã, e Harã, e Rezefe, e os filhos de Éden que estavam em Telassar?
13 Níbo ni ọba Hamati wà, ọba Arpadi, ọba ìlú Sefarfaimi tàbí Hena tàbí Iffa?”
13 Onde está o rei de Hamate e o rei de Arpade, e o rei da cidade de Sevarfaim, Hena e Iva?
14 Hesekiah gba ìwé náà lọ́wọ́ àwọn oníṣẹ́ ó sì kà á. Lẹ́yìn náà ni ó gòkè lọ sí tẹmpili Olúwa ó sì tẹ́ ìwé náà sílẹ̀ níwájú Olúwa.
14 E Ezequias recebeu a carta da mão dos mensageiros e a leu. E Ezequias subiu à casa do SENHOR e a estendeu perante o SENHOR.
15 Hesekiah sì gbàdúrà sí Olúwa:
15 E Ezequias orou ao SENHOR, dizendo:
16 Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli, tí ó gúnwà láàrín àwọn kérúbù, ìwọ nìkan ni Ọlọ́run lórí i gbogbo ìjọba orílẹ̀ ayé. Ìwọ ti dá ọ̀run àti ayé.
16 Ó SENHOR dos Exércitos, Deus de Israel, que habitas entre os querubins. Tu és o Deus, tu somente, de todos os reinos da terra. Tu tens feito céu e terra.
17 Tẹ́tí sílẹ̀, ìwọ Olúwa, kí o gbọ́, ya ojú rẹ, Ìwọ Olúwa, kí o rí i; tẹ́tí sí gbogbo ọ̀rọ̀ tí Sennakeribu rán láti fi àbùkù kan Ọlọ́run alààyè.
17 Inclina teu ouvido, Ó SENHOR, e ouça. Abre teus olhos, Ó SENHOR, e vê. Ouças todas as palavras de Senaqueribe, as quais tem enviado para desonrar o Deus vivo.
18 “Òtítọ́ ni Olúwa pé àwọn ọba Asiria ti sọ àwọn ènìyàn àti ilẹ̀ wọn di asán.
18 Com certeza, SENHOR, os reis da Assíria têm devastado todas as nações e seus territórios.
19 Wọ́n ti da àwọn òrìṣà wọn sínú iná wọ́n sì ti pa wọ́n run, nítorí àwọn wọ̀nyí kì í ṣe ọlọ́run bí kò ṣe igi àti òkúta lásán, tí a ti ọwọ́ ènìyàn ṣe.
19 E têm lançado seus deuses em direção ao fogo, pois eles não eram deuses, porém, o trabalho de mãos humanas, madeira e pedra. Por este motivo eles os têm destruído.
20 Nísinsin yìí, ìwọ Olúwa, Ọlọ́run wa, gbà wá lọ́wọ́ rẹ̀, tí ó fi jẹ́ pé gbogbo ìjọba ilẹ̀ ayé yóò fi mọ̀ pé Ìwọ, Ìwọ nìkan, Olúwa ni Ọlọ́run.”
20 Agora, portanto, Ó SENHOR nosso Deus, salva-nos da mão dele para que todos os reinos da terra possam saber que tu és o SENHOR, precisamente tu, unicamente.
21 Lẹ́yìn náà Isaiah ọmọ Amosi rán iṣẹ́ kan sí Hesekiah: “Èyí ni ohun tí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli sọ pé, nítorí pé ìwọ ti gbàdúrà sí mi nípa Sennakeribu ọba Asiria,
21 Então, Isaías, o filho de Amós, enviou a Ezequias, dizendo: Assim diz o SENHOR Deus de Israel: Considerando que tu tens orado a mim contra Senaqueribe, rei da Assíria.
22 èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa ti sọ nípa rẹ̀:
22 Esta é a palavra que o SENHOR tem falado a respeito dele. A virgem, a filha de Sião, tem te desprezado, e rido de ti com desdém. A filha de Jerusalém tem meneado a cabeça em direção a ti.
23 Ta ni ìwọ ti bú tí ìwọ sì ti sọ̀rọ̀-òdì sí?
23 A quem tu tens afrontado e blasfemado? E contra quem tu tens elevado tua voz e erguido teus olhos ao alto? Contra o Santo de Israel.
24 Nípa àwọn ìránṣẹ́ rẹ,
24 Por meio de teus servos tu tens afrontado o Senhor, e tens dito: Pela multidão das minhas carruagens estou subindo para o cume dos montes, para os lados do Líbano, e eu derrubarei os altos cedros daquele lugar e os ciprestes escolhidos dali. E entrarei em direção à região mais alta de sua fronteira e à floresta do seu Carmelo.
25 Èmi ti gbẹ́ kànga ní ilẹ̀ àjèjì
25 Eu tenho cavado e bebi água. Com a planta dos meus pés tenho eu secado todos os rios dos lugares sitiados.
26 “Ṣé o kò tí ì gbọ́?
26 Não tens tu ouvido desde tempos remotos, como eu tenho feito isto e desde tempos antigos, que eu o concebi? Agora, eu tenho trazido isto a ocorrer, na expectativa de que tu devas estar a devastar cidades protegidas em amontoados de ruínas.
27 Àwọn ènìyàn, tí agbára ti wọ̀ lẹ́wù,
27 Por esse motivo, seus habitantes foram de pouca força, eles ficaram consternados e confundidos. Eles eram como a grama do campo e como a erva verde, como o mato sobre os telhados, e como trigo danificado antes de estar completamente desenvolvido.
28 “Ṣùgbọ́n mo mọ ibi tí o wà
28 Porém, eu conheço tua moradia, e o teu sair e o teu entrar, e tua ira contra mim.
29 Nítorí pé inú rẹ ru sí mi
29 Porque tua ira contra mim e o teu tumulto está manifesto aos meus ouvidos. Portanto, colocarei meu anzol em teu nariz e minha rédea em teus lábios e te farei voltar pelo caminho pelo qual tu vieste.
30 “Èyí ni yóò ṣe àmì fún ọ, ìwọ Hesekiah:
30 E isto será um sinal para ti. Vós comereis este ano o que crescer por si mesmo e o segundo ano aquilo que brotar do mesmo. E no terceiro ano, semeai vós e colhei; e plantai vinhas e comei o fruto dali.
31 Lẹ́ẹ̀kan sí i, àṣẹ́kù láti ilé Juda
31 E o remanescente da casa de Judá que escapa novamente irá lançar raízes para baixo, e produzir frutos para cima.
32 Nítorí láti Jerusalẹmu ni àwọn àṣẹ́kù yóò ti wá,
32 Pois, para fora de Jerusalém sairá um remanescente, e daqueles que escaparem do Monte Sião. O zelo do SENHOR dos Exércitos fará isto.
33 “Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa wí nípa ọba Asiria,
33 Portanto, assim diz o SENHOR a respeito do rei da Assíria: Ele não adentrará esta cidade, nem atirará uma flecha ali, nem comparecerá perante ela com escudos, nem levantará uma rampa contra ela.
34 Nípa ọ̀nà tí ó gbà wá náà ni yóò padà lọ;
34 Pelo caminho que ele veio, pelo mesmo ele retornará, e não adentrará esta cidade, diz o SENHOR.
35 “Èmi yóò dáàbò bo ìlú yìí èmi ó sì gbà á là,
35 Porquanto, eu defenderei esta cidade para salvá-la, por amor de mim mesmo e por amor de meu servo Davi.
36 Lẹ́yìn náà ni angẹli Olúwa jáde lọ ó sì pa ọ̀kẹ́ mẹ́sàn-án ó lé ẹgbẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (185,000) ènìyàn ní i ibùdó àwọn Asiria. Nígbà tí àwọn ènìyàn yìí jí ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì gbogbo wọn ti dòkú!
36 Então, o anjo do SENHOR saiu e golpeou no campo dos assírios, cento e oitenta e cinco mil. E quando levantaram-se cedo pela manhã, eis que eles eram todos corpos mortos.
37 Nítorí náà Sennakeribu ọba Asiria fọ́ bùdó ó sì pẹsẹ̀dà. Òun sì padà sí Ninefe, ó sì dúró síbẹ̀.
37 Então, Senaqueribe rei da Assíria partiu, e foi, e retornou, e habitou em Nínive.
38 Ní ọjọ́ kan, bí ó ti ń jọ́sìn nínú tẹmpili Nisroki òrìṣà rẹ̀, àwọn ọmọ rẹ̀ Adrameleki àti Ṣareseri gé e lulẹ̀ pẹ̀lú idà, wọ́n sì sálọ sí ilẹ̀ Ararati. Bẹ́ẹ̀ ni Esarhadoni ọmọ rẹ̀ sì gba ipò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
38 E, aconteceu que enquanto ele estava adorando na casa de Nisroque, seu deus, Adrameleque e Sarezer, seus filhos, o golpearam com a espada e escaparam em direção à terra da Armênia; e Esar-Hadom, seu filho, reinou em seu lugar.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Isaías 37, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.