Isaías 19

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NAA

Sair da comparação
NAA Nova Almeida Atualizada 2017
1 Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Ejibiti.
1 Sentença contra o Egito. Eis que o uma nuvem ligeira, vai indo para o Egito. Os ídolos do Egito estremecerão diante dele, e o coração dos egípcios se derreterá dentro deles.
2 “Èmi yóò rú àwọn ará Ejibiti sókè sí ara wọn
2 “Porque farei com que egípcios se levantem contra egípcios, e cada um lutará contra o seu irmão e cada um contra o seu próximo; cidade contra cidade, reino contra reino.
3 Àwọn ará Ejibiti yóò sọ ìrètí nù,
3 O espírito dos egípcios irá esmorecer dentro deles, e eu farei com que os planos deles fracassem. Eles consultarão os seus ídolos, encantadores, médiuns e feiticeiros.
4 Èmi yóò fi Ejibiti lé agbára
4 Entregarei os egípcios nas mãos de um senhor cruel, e um rei feroz os dominará”, diz o Senhor, o
5 Gbogbo omi inú odò ni yóò gbẹ,
5 As águas do mar baixarão, e o rio Nilo se tornará seco e árido.
6 Adágún omi yóò sì di rírùn;
6 Os canais exalarão mau cheiro, e os braços do Nilo diminuirão até secar; as canas e os juncos murcharão.
7 àwọn igi ipadò Naili pẹ̀lú,
7 A relva que está junto ao Nilo, junto às suas margens, e tudo o que foi semeado junto dele secarão, serão levados pelo vento e desaparecerão.
8 Àwọn apẹja yóò sọkún kíkorò,
8 Os pescadores gemerão, e lamentarão todos os que lançam anzóis no rio; e os que estendem redes sobre as águas desfalecerão.
9 Àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ọ̀gbọ̀ yóò kọminú
9 Os que trabalham em linho fino e os que tecem pano de algodão ficarão decepcionados.
10 Àwọn tí ń ṣiṣẹ́ aṣọ yóò rẹ̀wẹ̀sì,
10 Os seus homens importantes serão esmagados, e todos os que trabalham por salário andarão de alma entristecida.
11 Àwọn oníṣẹ́ Ṣoani ti di aláìgbọ́n,
11 Na verdade, os príncipes de Zoã não têm juízo; os sábios conselheiros de Faraó dão conselhos estúpidos. Como vocês podem dizer ao Faraó: “Sou filho de sábios, filho de antigos reis?”
12 Níbo ni àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn rẹ wà báyìí?
12 Onde estão agora os seus sábios? Que eles agora lhe anunciem ou informem o que o determinou contra o Egito.
13 Àwọn ọmọ-aládé Ṣoani ti di aṣiwèrè,
13 Os príncipes de Zoã perderam o juízo, e os príncipes de Mênfis estão enganados; os que são a pedra de esquina das suas tribos estão levando o Egito a andar errante.
14 Olúwa ti da ẹ̀mí òòyì sínú wọn;
14 O Senhor derramou no coração deles um espírito de confusão; eles fizeram o Egito andar errante em toda a sua obra, como o bêbado quando escorrega no seu próprio vômito.
15 Kò sí ohun tí Ejibiti le ṣe—
15 Para o Egito, não há obra alguma que possa ser feita pela cabeça ou cauda, pela palma ou junco.
16 Ní ọjọ́ náà ni àwọn ará Ejibiti yóò dàbí obìnrin. Wọn yóò gbọ̀n jìnnìjìnnì pẹ̀lú ẹ̀rù nítorí ọwọ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tí a gbé sókè sí wọn.
16 Naquele dia, os egípcios serão como mulheres: ficarão tremendo de medo quando se levantar a mão do Senhor dos Exércitos, que ele agitará contra eles.
17 Ilẹ̀ Juda yóò sì di ẹ̀rù fún Ejibiti; gbogbo àwọn tí a bá ti dárúkọ Juda létí wọn ni yóò wárìrì, nítorí ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun gbèrò láti ṣe sí wọn.
17 A terra de Judá será um espanto para o Egito; todo aquele que dela se lembrar ficará apavorado por causa da decisão que o Senhor dos Exércitos tomou contra eles.
18 Ní ọjọ́ náà ìlú márùn-ún ní ilẹ̀ Ejibiti yóò sọ èdè àwọn ará Kenaani, wọn yóò sì búra àtìlẹ́yìn fún Olúwa àwọn ọmọ-ogun. Ọ̀kan nínú wọn ni a ó sì máa pè ní ìlú ìparun.
18 Naquele dia, haverá cinco cidades na terra do Egito que falarão a língua de Canaã e farão juramento ao Senhor dos Exércitos; uma delas se chamará Cidade do Sol.
19 Ní ọjọ́ náà pẹpẹ kan yóò wà fún Olúwa ní àárín gbùngbùn Ejibiti, àti ọ̀wọ́n kan fún Olúwa ní etí bodè rẹ̀.
19 Naquele dia, o Senhor terá um altar no meio da terra do Egito, e na fronteira do país será levantada uma coluna em honra do Senhor .
20 Yóò sì jẹ́ àmì àti ẹ̀rí sí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ní ilẹ̀ Ejibiti. Nígbà tí wọ́n bá ké pe Olúwa nítorí àwọn aninilára wọn, yóò rán olùgbàlà àti olùgbèjà kan sí wọn tí yóò sì gbà wọ́n sílẹ̀.
20 Servirá de sinal e de testemunho ao Senhor dos Exércitos na terra do Egito. Quando eles clamarem ao Senhor por causa dos opressores, ele lhes enviará um salvador e defensor que os há de livrar.
21 Báyìí ni Olúwa yóò sọ ara rẹ̀ di mí mọ̀ fún àwọn ará Ejibiti àti ní ọjọ́ náà ni wọn yóò gba Olúwa gbọ́. Wọn yóò sìn ín pẹ̀lú ẹbọ ọrẹ ìyẹ̀fun, wọn yóò jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa wọn yóò sì mú un ṣẹ.
21 O Senhor se dará a conhecer ao Egito, e os egípcios conhecerão o Senhor naquele dia. Eles o adorarão com sacrifícios e ofertas de cereais, e farão votos ao Senhor , e os cumprirão.
22 Olúwa yóò fi àjàkálẹ̀-ààrùn kan bá Ejibiti jà; yóò bá wọn jà yóò sì tún wò wọ́n sàn. Wọn yóò yípadà sí Olúwa, Òun yóò sì gbọ́ ẹ̀bẹ̀ wọn yóò sì wò wọ́n sàn.
22 O Senhor ferirá os egípcios; ele os ferirá, mas depois os curará. Eles se converterão ao Senhor , e ele lhes atenderá as orações e os curará.
23 Ní ọjọ́ náà òpópónà kan yóò wá láti Ejibiti lọ sí Asiria. Àwọn ará Asiria yóò lọ sí Ejibiti àti àwọn ará Ejibiti lọ sí Asiria. Àwọn ará Ejibiti àti ará Asiria yóò jọ́sìn papọ̀.
23 Naquele dia, haverá uma estrada do Egito até a Assíria. Os assírios irão ao Egito, e os egípcios irão à Assíria; e os egípcios adorarão com os assírios.
24 Ní ọjọ́ náà Israẹli yóò di ẹ̀kẹta pẹ̀lú Ejibiti àti Asiria, àní orísun ìbùkún ní ilẹ̀ ayé.
24 Naquele dia, Israel será o terceiro com os egípcios e os assírios, uma bênção no meio da terra.
25 Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò bùkún wọn yóò wí pé, “Ìbùkún ni fún Ejibiti ènìyàn mi, Asiria iṣẹ́ ọwọ́ mi, àti Israẹli ìní mi.”
25 O Senhor dos Exércitos os abençoará, dizendo: “Bendito seja o Egito, meu povo! Bendita seja a Assíria, obra de minhas mãos. E bendito seja Israel, minha herança.”

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Isaías 19, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.