Hebreus 2
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Nítorí náà, ó yẹ kí àwa máa fi iyè sí àwọn nǹkan wọ̀n-ọn-nì gidigidi tí àwa ti gbọ́, kí a má ba à gbá wa lọ kúrò nínú wọn nígbà kan.
1 Anayabin iti isan tur anababatun hio tanonowar i tanabukikin gewas, saise it boro men au uf tanabatamih.
2 Nítorí bí ọ̀rọ̀ tí a tí ẹnu àwọn angẹli sọ bá sì dúró ṣinṣin, àti tí olúkúlùkù ẹ̀ṣẹ̀ sí òfin àti àìgbọ́ràn gba ìjìyà tí ó tọ́ sí i,
2 Tur tounamatar hibai hina ata a’agir hibitih i tur anababatun naatu orot babin ta iti tur men bosiyasiyar bi’ufunun i baimakiy baib.
3 kín ni ohun náà tí ó mú wa lérò pé a lè bọ́ kúrò nínú ìjìyà bí a kò bá náání ìgbàlà ńlá yìí? Ìgbàlà tí Olúwa fúnra rẹ̀ kọ́kọ́ kéde, èyí tí a sì fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ fún wa láti ọwọ́ àwọn tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ náà lẹ́nu rẹ̀.
3 It yawas gagamin isan ata not men gagamin tanabitin na’at, boro mi’itube tanahaiw? Anayabin iti yawas isan Regah taiyuwin wantoro’ot kurereb, naatu sabuw iyab hinowar hibai hina hibi’obaiyit hio, “Iti tur i turobe.”
4 Ọlọ́run jẹ́rìí sí i nípa àwọn iṣẹ́ àmì àti ìyanu àti oríṣìíríṣìí iṣẹ́ agbára àti nípa ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́ tí a pín gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ rẹ̀.
4 Nati veya ta’imon wanawananamaim God ana sifruborubon tur tafan ya’abar bai tit i arih auman ita’imon ina’inan yumatah ta ta naatu baifofofor yumatah ta ta sinaf. Naatu i ana kokomaim Anun Kakafiyin ana usar ta’ita’imon faram.
5 Nítorí pé, kì í ṣe abẹ́ ìṣàkóso àwọn angẹli ni ó fi ayé tí ń bọ̀, tí àwa ń sọ̀rọ̀ rẹ̀ sí.
5 Tafaram boubun boro enan bonawiyin isan God men tounamatar rubinih boro i hinabonawiy en, tafaram boubun ana tur iti tao.
6 Ṣùgbọ́n ibìkan wà tí ẹnìkan tí jẹ́rìí pé
6 Baise Buk Atamanin wanawanan efan ta’ane i iti na’atube eo,
7 Ìwọ dá a ní onírẹ̀lẹ̀ díẹ̀ ju àwọn angẹli lọ;
7 Mar kafai iyare tounamatar etei babahimaim,
8 Ìwọ fi ohun gbogbo sábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.”
8 Naatu sawar tutufin etei bai’ukwarin isan ana fair itin.”
9 Ṣùgbọ́n àwa rí Jesu ẹni tí a rẹ̀ sílẹ̀ díẹ̀ ju àwọn angẹli lọ fún àkókò díẹ̀, àní Jesu, ẹni tí a fi ògo àti ọlá dé ní adé nítorí ìjìyà wa; kí ó lè tọ́ ikú wò fún olúkúlùkù ènìyàn nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run.
9 Baise Jesu i ta’i’itin, God yare re tounamatar babahimaim, naatu God ana bosiyasiyaramaim sabuw etei isah morob. Naatu boun ana aiwob baib i marakaw baifa’en bora’ara’aten hinitin, anayabin morobomaim biyababan bai.
10 Nítorí pé ó yẹ fún Ọlọ́run, nítorí nípasẹ̀ ẹni tí ohun gbogbo ṣẹ̀ wà, láti mú àwọn ọmọ púpọ̀ wá sínú ògo, láti ṣe balógun ìgbàlà wọn ni àṣepé nípa ìjìyà.
10 God akisin ana kokomaim sawar himatar, naatu ana kokomaim sawar etei tema’am, imih iwa’an Jesu biyababanamaim rusouw, saise God natunatun moumurih na’in nabonawiyih hinarun bairi ana aiwob hinafaram. Anayabin Jesu akisinamo boro sabuw nabonawiyih yawas nitih.
11 Nítorí àti ẹni tí ń sọ ni di mímọ́ àti àwọn tí a ń sọ di mímọ́, láti ọ̀dọ̀ ẹnìkan ṣoṣo ni gbogbo wọn ti wá, nítorí èyí ni kò ṣe tijú láti pè wọ́n ni arákùnrin.
11 Naatu sabuw hai kakafihine kukusouwih ufunamaim bairi hina tamah ta’imon himatar. Imih Jesu boro men biya’ohow auman taitin narouw na’omih.
12 Àti wí pé,
12 Naatu Jesu God isan eo,
13 Àti pẹ̀lú,
13 Naatu eo maiye,
14 Ǹjẹ́ ni ìwọ̀n bí àwọn ọmọ tí ṣe alábápín ará àti ẹ̀jẹ̀, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni òun pẹ̀lú sì ṣe alábápín nínú ohun kan náà; kí ó lè ti ipa ikú rẹ̀ pa ẹni tí ó ní agbára ikú run, èyí ni èṣù.
14 Imih it God natunatun biyat finimit rara auman eo tamatar. Jesu i na’atube orot babin biyah turin bai. Orot babin na’atube tufuw biyat ebababan na’atube biyan baban morob, Demon morob ana fair bai ma’am gurus.
15 Kí o sì lè gba gbogbo àwọn tí ó tìtorí ìbẹ̀rù ikú wà lábẹ́ ìdè lọ́jọ́ ayé wọn gbogbo kúrò lọ́wọ́ ìbẹ̀rù.
15 Naatu sabuw hai yawas tutufin etei demon ana dibur hirun morob isan hima hibirubir rufamih hitit Jesu tibitumatum.
16 Nítorí pé, nítòótọ́, kì í ṣe àwọn angẹli ni ó ṣe ìrànlọ́wọ́ fún, ṣùgbọ́n àwọn irú-ọmọ Abrahamu ni ó ṣe ìrànlọ́wọ́ fún.
16 Anayabin Jesu ana baibais i bebeyan ta’itin, i men tounamatar baibaisih isan namih. Baise Buk Atamaninamaim eo na’atube, “Abraham wawawan baibaisihimih na.”
17 Nítorí náà, ó yẹ pé nínú ohun gbogbo kí ó dàbí àwọn ará rẹ̀, kí ó lè jẹ́ aláàánú àti olóòtítọ́ alábojútó Àlùfáà nínú ohun tí i ṣe ti Ọlọ́run, kí o lè ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn.
17 Ana’an iti, imih Jesu na taitin hai yawas wanawanan run sora’ub, saise i ana bowabow Firis Gagamin na’atube God isan, taitin isah boro turobe’emaim nakabibirih, sabuw hai bowabow kakafihine boro notawiyen hinab.
18 Nítorí níwọ̀n bí òun tìkára rẹ̀ ti jìyà tí a sì ti dán an wò, òun ní agbára láti ran àwọn tí a ń dánwò lọ́wọ́.
18 Naatu boun i karam sabuw iyab routobon tebaib boro nibaisih, anayabin i auman routobon bai naatu biyan baban i’akir.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Hebreus 2, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.