Hebreus 12

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Nítorí náà bí a ti fi ìkùùkuu àwọsánmọ̀ tí o kún fún àwọn ẹlẹ́rìí tó báyìí yí wa ká, ẹ jẹ́ kí a pa ohun ìdíwọ́ gbogbo tì sí apá kan, àti ẹ̀ṣẹ̀ tí o rọrùn láti di mọ́ wa, kí a sì máa fi sùúrù súré ìje tí a gbé ka iwájú wa,
1 Isan imih it i sabuw maramaim kau’ay gagamin na’in sisibit roun roun hi’ar bebera’uh hibat hi’itit tanununuw. Imih sawar kakafih erorowen tanit tanisrouwen naatu bowabow kakafihine fatumit tama’am tanarufamit tanatit, nunuwamih hi’u’uwit saise tanitarfofor tananunuw gewas.
2 kí a máa wo Jesu Olùpilẹ̀ṣẹ̀ àti aláṣepé ìgbàgbọ́ wa; ẹni nítorí ayọ̀ tí a gbé ka iwájú rẹ, tí o faradà àgbélébùú láìka ìtìjú sí, tí ó sì jókòó lọ́wọ́ ọ̀tún ìtẹ́ Ọlọ́run.
2 Matat etei Jesu tana’itin, ata baitumatum an naatu yomanin, sabuw hibai onaf afe’en hi’onaf hibi’i’iyab, men biyan eohow. Anayabin yasisir nanamaim ma’am i so’ob, imih wainab in yomaninamaim yen God ana asukwafune mare bonamanamarinamaim ema’am.
3 Máa ro ti ẹni tí ó faradà irú ìsọ̀rọ̀-òdì yìí láti ọ̀dọ̀ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ si ara rẹ̀, kí ẹ má ba á rẹ̀wẹ̀sì ni ọkàn yín, kí àárẹ̀ si mu yín.
3 Sabuw kakafih wanawanahimaim wawainab i kwananot, isan imih kwa men kwanahahar naatu gubam nahuriramih.
4 Ẹ̀yin kò sá à tí ì kọ ojú ìjà si ẹ̀ṣẹ̀ títí dé títa ẹ̀jẹ̀ yín sílẹ̀ nínú ìjàkadì yín.
4 Anayabin bowabow kakafih bairi kwabiyow ana veya kwa men yait hi’asbuni imorobomih.
5 Ẹ̀yin sì ti gbàgbé ọ̀rọ̀ ìyànjú tí ó n ba yin sọ̀rọ̀ bí ọmọ pé,
5 Buk Atamaninamaim God kwa i natunatun rouw koufair tur bit kwanotanot? Iti na’atube eo,
6 nítorí pé ẹni ti Olúwa fẹ́, òun ni i bá wí,
6 Anayabin Regah orot babin iyab isah ebiyabow boro baikwatutunen nitih, naatu orot babin iyab i natunatunamih ebowabow boro baimakiy nitih.”
7 Ẹ máa ní sùúrù lábẹ́ ìbáwí, Ọlọ́run bá wa lò bí ọmọ ni; nítorí pé ọmọ wo ni ń bẹ ti baba kì í bá wí?
7 Biyababan fokarih wanawanan kwana fair nawainabi nati i kwa a baikwatutunen na’atube, anayabin kwa i natunatun imih ebi’obaiyi. It tamatanah baikwatutunen titit tibi’obaiyit i kwaso’ob.
8 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin ba wà láìsí ìbáwí, nínú èyí tí gbogbo ènìyàn ti jẹ alábápín, ǹjẹ́ ọmọ àlè ni yín, ẹ kì í sì ṣe ọmọ.
8 God natunatun etei baikwatutunen ebitih, naatu o baikwatutunen men inabaib na’at, nati ana itinin o i men natun anababatun. O i tamat en, ometakek.
9 Pẹ̀lúpẹ̀lú àwa ni baba wa nípa ti ara tí o ń tọ́ wa, àwa sì ń bu ọlá fún wọn: kò ha yẹ kí a kúkú tẹríba fún Baba àwọn ẹ̀mí, kí a sì yè?
9 Kek ana veya, tamatanah baikwatutunen hibitit i taso’ob, naatu takakafiyih. Imih Tamat maramaim baikwatutunen nabitit ana maramaim tanakakafiy gewas, saise boro ma’ama wanatowanamaim tanama.
10 Nítorí wọ́n tọ́ wa fún ọjọ́ díẹ̀ bí o bá ti dára lójú wọn; ṣùgbọ́n Òun tọ́ wa fún èrè wa, kí àwa lè ṣe alábápín ìwà mímọ́ rẹ̀.
10 Tamatanah baikwatutunen titit tibi’obaiyit, nati i it ata ma gewasin isan. Baise God baikwatutunen ebitit i turobe naatu gewasin, anayabin i ekokok, i ana kakafiyin bairi tanafaram.
11 Gbogbo ìbáwí kò dàbí ohun ayọ̀ nísinsin yìí bí kò ṣe ìbànújẹ́; ṣùgbọ́n níkẹyìn yóò so èso àlàáfíà fún àwọn tí a tọ́ nípa rẹ̀, àní èso òdodo.
11 Baikwatutunen tabaib ana veya’amaim biyat i ebababan tarererey naatu men tabiyasisir. Baise biyababan ufunamaim sabuw iyab baikwatutunen hibai hibi’akir hai yawas boro namutufor yasisiramaim hinama gewas.
12 Nítorí náà, ẹ na ọwọ́ tí ó rọ, àti eékún àìlera,
12 Isan imih kwanunuw uma tehahahar kwana’awanfairen, naatu a hiririm ra’iyemih kwabiwa’an kwanabat gewas.
13 “Kí ẹ sì ṣe ipa ọ̀nà tí ó tọ́ fún ẹsẹ̀ yin,” kí èyí tí ó rọ má bá a kúrò lórí ike ṣùgbọ́n kí a kúkú wò ó sàn.
13 A i namutufor efatut kwanan, saise sabuw afa ah umah ririmih naatu kiyatabirih kwa hi’ufnuni tenan boro men hinawasdidir hinare, baise kwane i boro hai fair hinab maiye hini’ufnuni.
14 Ẹ máa lépa àlàáfíà pẹ̀lú ènìyàn gbogbo, àti ìwà mímọ́, láìsí èyí yìí kò sí ẹni tí yóò rí Olúwa.
14 Kwanasinaftobon taituwa bairi tufuwamaim kwanama, naatu kwanayasairi kakafiyinamaim kwanama. Anayabin orot yait ana yawas men ya’asair kakafiyinamaim ema’am Regah ana yumat boro men na’itin.
15 Ẹ máa kíyèsára kí ẹnikẹ́ni má ṣe kùnà Oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run; kí gbòǹgbò ìkorò kan máa ba hù sókè kí ó sì yọ yín lẹ́nu, ọ̀pọ̀lọpọ̀ a sì ti ipa rẹ̀ di àìmọ́.
15 Mata toniwa’an gewas, men yait ta God ana manaw ana kabeberane namatabiramih. Kwana’itin gewas men yait ta kwa wanawanamaim ihitutu na’atube ub nakufaifaiy, naatu ana fafa’amaim sawar etei hinakokoramih.
16 Kí o má bá à si àgbèrè kan tàbí aláìwà-bí-Ọlọ́run bi Esau, ẹni tí o tìtorí òkèlè oúnjẹ kan ta ogún ìbí rẹ̀.
16 Kwana’itin gewas men yait ta na’in nisesebar kwanekwanemih, o Esau sisinaf na’atube nasinaf koun God nitinimih. Anayabin Esau bay tew ta’imonamaim kek ai’in hai onowaten sawar tutufin etei bora’ah tain itin.
17 Nítorí ẹ̀yin mọ pé lẹ́yìn náà, nígbà tí ó fẹ́ láti jogún ìbùkún náà, a kọ̀ ọ́, nítorí kò ri ààyè ìrònúpìwàdà, bí o tilẹ̀ jẹ́ pé ó fi omijé wa a gidigidi.
17 Naatu sawar abisa uf himamatar i kwaso’ob, Esau tamah ana baigegewasin isan erererey auman bifefeyan tamah rutawiy. Anayabin abisa marasika sisinaf men dogor baikitabir bai.
18 Nítorí ẹ̀yin kò wá òkè tí a lè fi ọwọ́ kàn, àti ti iná ti ń jó, àti ti ìṣúdudu àti òkùnkùn, àti ìjì.
18 Kwa i men kwana oyaw an kwatit Israel sabuw sawar hi’i’itin na’atube kwa’itinimih. Anayabin Israel sabuw hina oyaw Sinai anamaim hititit ana veya wairaf in bitakir hi’itin, gugumin kakafin anababatun hi’itin, wowog gagamin maiyow re’er hi’itin. Naatu nidun hinonowar i
19 Àti ìró ìpè, àti ohùn ọ̀rọ̀, èyí tí àwọn tí o gbọ́ bẹ̀bẹ̀ pé, kí a má ṣe sọ ọ̀rọ̀ sí i fún wọn mọ́,
19 tour nidun hinowar, naatu orot fanan hinonowar ana veya yah birubir fafar Moses hi’u, “Orot ku’otan aki men akokok tur ta nao maiye ananowar.”
20 nítorí pé wọn kò lè gba ohun tí ó paláṣẹ, “Bí o tilẹ̀ jẹ ẹranko ni ó fi ara kan òkè náà, a ó sọ ọ́ ni òkúta.”
20 Anayabin God ana ofafar tur fokarin iti na’atube eo isan i hibir, “Bobaituw ta nan iti oyaw sisibinamaim natit nabubutubun na’at kabayamaim kwanarab namorob.”
21 Ìran náà sì lẹ́rù to bẹ́ẹ̀ tí Mose wí pé, “Ẹ̀rù ba mi gidigidi mo sì wárìrì.”
21 Abisa matahimaim hi’i’itin i hai bir ra’at, Moses auman ana bir ra’at eo, “Ayu iti sawar aitin abir au umau teo’oror.”
22 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin wá sí òkè Sioni, àti sí ìlú Ọlọ́run alààyè, ti Jerusalẹmu ti ọ̀run, àti si ẹgbẹ́ àwọn angẹli àìníye,
22 Baise boun kwa i kwana oyaw wabin Zion imaim kwatit, God wanatowan ma’ama’anin ana bar ana merar, mar ana Jerusalem, tounamatar kou’ay gagamin na’in dones na’atube tibiyasisir wanawanah kwarun bairi kwabiyasisir.
23 si àjọ ńlá tí ìjọ àkọ́bí tí a ti kọ orúkọ wọn ni ọ̀run, àti sọ́dọ̀ Ọlọ́run onídàájọ́ gbogbo ènìyàn, àti sọ́dọ̀ àwọn ẹ̀mí olóòtítọ́ ènìyàn tí a ṣe ni àṣepé,
23 Kwa i kwana God natunatun ai’in hai yasisir wanawanan kwarun, natunatun wabih maramaim hikikirum, kwa i kwana sabuw etei hai baibatiyenayan ana God biyan kwanatit. Naatu sabuw gewasih ayubih kouksouwen hibaika tema’am biyah kwatit.
24 àti sọ́dọ̀ Jesu alárinà májẹ̀mú tuntun, àti si ibi ẹ̀jẹ̀ ìbùwọ́n ni, ti ń sọ̀rọ̀ ohun tí ó dára ju ti Abeli lọ.
24 Kwana Jesu obaibasit boubun ana foun batayan biyan kwatit naatu rara boubun suware’er i igewasin kwanekwan men Abel ana rara na’atube.
25 Kíyèsi i, kí ẹ má ṣe kọ̀ ẹni tí ń kìlọ̀. Nítorí bí àwọn wọ̀nyí kò bá bọ́ nígbà tí wọn kọ̀ ẹni ti ń kìlọ̀ ni ayé, mélòó mélòó ni àwa kì yóò bọ́, bí àwa ba pẹ̀yìndà sí ẹni tí ń kìlọ̀ láti ọ̀run wá,
25 Kwana’itin gewas God abisa boun eo kwananowar, men kwanakwahir. Anayabin sabuw iyab marasika oyaw anamaim Moses eo hinowar fanan hisasair i baimakiy men kafa’imo hihaiwimih. Naatu boun God fanan i mutufor marane re eo tanonowar, baise kwanitafasar fanan kwanasasair na’at, kwa i kwamorob sawar. Baimakiy kakafin anababatun boro men karam kwanahaiw!
26 ohùn ẹni tí ó mi ayé nígbà náà, ṣùgbọ́n nísinsin yìí o ti ṣe ìlérí, wí pé, “Lẹ́ẹ̀kan sí i èmi ki yóò mi kìkì ayé nìkan, ṣùgbọ́n ọ̀run pẹ̀lú.”
26 Oyaw Sinai anamaim i fananawat eo, me etei i’uruyuy, baise boun it ata veya’amaim ana omatanen hikirum inu’in na’atube boro namatar, “Veya ta boro men me akisin aniyuwiyuw, baise mar tafaram etei boro aniyuwiyuw.”
27 Àti ọ̀rọ̀ yìí, “Lẹ́ẹ̀kan sí i,” ìtumọ̀ rẹ̀ ni, mímú àwọn ohun wọ̀nyí ti a ń mì kúrò, bí ohun tí a ti dá, kí àwọn ohun tí a kò lè mì lè wà síbẹ̀.
27 Tur mar ta’imon i bebeyan i’obaiyit taitin, God umanamaim abisa eo himatar tema’am boro etei niyuwiyuw hai efan hinasa’iren. Baise sawar abisa wanatowan ma’amih bimataren boro hai efanika hinama.
28 Nítorí náà bí àwa tí ń gbà ilẹ̀ ọba ti a kò lè mì, ẹ jẹ́ kí a dá ọpẹ́ nípa èyí ti a fi lè máa sin Ọlọ́run ni ìtẹ́wọ́gbà pẹ̀lú ọ̀wọ̀ àti ìbẹ̀rù rẹ̀.
28 Imih God ana merar tanay anayabin, it i God ana aiwobomaim tarun, nati efan God boro men niyuwiyuw. Imih God tanifai tanabora’ara’ah ata not tutufin etei kakaf bir auman.
29 Nítorí pé, “Ọlọ́run wa, iná ti ń jó ni run ni.”
29 Anayabin ata God i turobe tafaram gurusenayan ana wairaf.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Hebreus 12, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.