Hebreus 11
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Ǹjẹ́ ìgbàgbọ́ ní ìdánilójú ohun tí o ń retí, ìjẹ́rìí ohun tí a kò rí.
1 Baitumatum ana itinin i sawar ta anababatun taso’ob ema’ama boro nuhi nafot tanama’am nati sawar tanab. Naatu sawar ta men ta’i’itin, baise taso’ob nati sawar i ema’am boro tanab, nati i boun baitumatum tao’o.
2 Nítorí nínú rẹ ni àwọn alàgbà àtijọ́ ní ẹ̀rí rere.
2 Imih ata a’agir marasika hima’ama hai baitumatumamaim God itin, ana baibasit itih.
3 Nípa ìgbàgbọ́ ni a mọ̀ pé a ti dá ayé nípa ọ̀rọ̀ Ọlọ́run; nítorí náà kì í ṣe ohun tí o hàn ni a fi dá ohun tí a ń ri.
3 Baitumatumamaim taso’ob tafaramamaim sawar etei i God awanamaim eo himatar, naatu iti sawar himamatar i men ta’i’itahimaim eo himataramih, baise buriburihimaim.
4 Nípa ìgbàgbọ́ ní Abeli rú ẹbọ sí Ọlọ́run tí ó sàn ju ti Kaini lọ, nípa èyí tí a jẹ́rìí rẹ̀ pe olódodo ni, Ọlọ́run sí ń jẹ́rìí ẹ̀bùn rẹ̀, àti nípa rẹ̀ náà, bí o ti jẹ́ pé o ti kú, síbẹ̀ o ń fọhùn.
4 Baitumatumamaim Abel siwar gewasinamak bai na God bitin i men Cain ana siwar na’atube’emih. Ana baitumatumamaim God iyasisir ana ef mutufurin rouw eo, anayabin ana siwar gewasin. Abel i marasik morob, baise ana baitumatumamaim fanan i ema’ama.
5 Nípa ìgbàgbọ́ ni a ṣí Enoku ní ipò padà kí o má ṣe rí ikú; a kò sì rí i mọ́, nítorí Ọlọ́run ṣí i ní ipò padà ṣáájú ìṣípò padà rẹ̀, a jẹ́rìí yìí sí i pé o wu Ọlọ́run.
5 Baitumatumamaim Enoch morobo’e, yawasin au mar yen, sabuw hinuwih men hitita’ur, anayabin God bora’ah. Baise au mar yena’e ana veya abisa sisinaf God itin eo, “O isa ayu abiyasisir.”
6 Ṣùgbọ́n láìsí ìgbàgbọ́ kò ṣe é ṣe láti wù ú; nítorí ẹni tí ó bá ń tọ Ọlọ́run wá kò lè ṣàì gbàgbọ́ pé ó ń bẹ, àti pé òun ní olùṣẹ̀san fún àwọn tí o fi ara balẹ̀ wá a.
6 Orot babin yait aurin baitumatum en God nati orot babin isan men ebiyasisir, anayabin orot babin yait God nanamaim titamih i nitumatum God i ema’am, naatu orot babin yait turobe’emaim enunuwih ana baiyan boro nitih.
7 Nípa ìgbàgbọ́ ni Noa, nígbà ti Ọlọ́run, kìlọ̀ ohun tí a kóò tí ì rí fún un, o bẹ̀rù Ọlọ́run ó sì kan ọkọ̀ fún ìgbàlà ilé rẹ̀, nípa èyí tí ó da ayé lẹ́bi, ó sì di ajogún òdodo tí i ṣe nípa ìgbàgbọ́.
7 Baitumatumamaim sawar abisa boro hitamatar isan God Noah bimatanuw ana veya, bir kakafiyinamaim God fanan bai wa wowab aawan natunatun bairi hiyawasih. Ana baitumatumamaim tafaram ana kakafinane kusib tabaratait tit nabin bat, naatu God biyanane yawas mutufurin bain ana baibasit ma’ama ana baitumatumamaim bai.
8 Nípa ìgbàgbọ́ ní Abrahamu, nígbà tí a ti pé e láti jáde lọ sí ibi tí òun yóò gbà fún ilẹ̀ ìní, ó gbọ́, ó sì jáde lọ, láì mọ ibi tí òun ń rè.
8 Baitumatumamaim Abraham tafaram ta boro uf i nowanamih tamamatar isan God eo’omatan ana veya’amaim, God fanan bai ana tafaram itumar misir asir remor kwaneyan in.
9 Nípa ìgbàgbọ́ ní o ṣe àtìpó ní ilẹ̀ ìlérí, bí ẹni pé ni ilẹ̀ àjèjì, o ń gbé inú àgọ́, pẹ̀lú Isaaki àti Jakọbu, àwọn ajogún ìlérí kan náà pẹ̀lú rẹ̀,
9 Baitumatumamaim Abraham na omatanen me’emaim tit, touman orot na’atube menah tatabirih hai tafaramamaim sis ya ma remor. Isaac naatu Jacob hairi auman na’atube hisinaf, anayabin i auman me nati isan God eomatanih.
10 nítorí tí ó ń retí ìlú tí ó ní ìpìlẹ̀; èyí tí Ọlọ́run tẹ̀dó tí ó sì kọ́.
10 Abraham sisimaim ma reremor anayabin i bitumatum bar merar gewasin anababatun God taiyuwin yakitifuw wowowab imaim boro narun wanatowan nitutut nama.
11 Nípa ìgbàgbọ́ ni Sara tìkára rẹ̀ pẹ̀lú fi gba agbára láti lóyún, nígbà tí ó kọjá ìgbà rẹ̀, nítorí tí o ka ẹni tí o ṣe ìlérí sí olóòótọ́.
11 Iban maiye kwana’itin, Abraham i iregah naatu Sarah i a’arin, baise baitumatumamaim Abraham, kek tamah matar, anayabin i so’ob God ana omatanen isah i mar etei ebobosunusunub.
12 Nítorí náà ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ṣe ti ara ọkùnrin kan jáde, àní ara ẹni tí o dàbí òkú, ọmọ bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run lọ́pọ̀lọ́pọ̀, àti bí iyanrìn etí Òkun láìníye.
12 Imih bebeyan tana’itin, Abraham biyan etei i morob, baise iti orot ta’imon biyanane ana ub ra’at tafaram awan karatan, daman naatu dones na’atube baiyabin en.
13 Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ó kú nínú ìgbàgbọ́, láìrí àwọn ìlérí náà gbà, ṣùgbọ́n tí wọn rí wọn ni òkèrè réré, tí wọ́n sì gbá wọn mú, tí wọ́n sì jẹ́wọ́ pé àlejò àti àjèjì ni àwọn lórí ilẹ̀ ayé.
13 Iti sabuw erebaitumatum hima’am himorob, sawar God eo’omatanih men hibai, baise hinuwamo ef yok na’in hi’itin, naatu yasisiramaim nati sawar hai merar hiyi. Imih taiyuwih isah iti tafaramamaim i nah toumanih naatu ef rimurih na’atube hima.
14 Nítorí pé àwọn tí o ń sọ irú ohun bẹ́ẹ̀ fihàn gbangba pé, wọn ń ṣe àfẹ́rí ìlú kan tí i ṣe tiwọn.
14 Anayabin sabuw sawar iti na’atube isah teo i tafaram ta bain nowah matar, imaim wanatowan ma’amih tinunuwet.
15 Àti nítòótọ́, ìbá ṣe pé wọ́n fi ìlú tiwọn tí jáde wá sí ọkàn, wọn ìbá ti rí ààyè padà.
15 Naatu hai tafaram atamanin hibihamiy isan hitanotanot na’at, marasika boro ef hitanuwet hitamatabir maiye.
16 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n ń fẹ́ ìlú kan tí o dára jù bẹ́ẹ̀ lọ, èyí yìí ni ti ọ̀run, nítorí náà ojú wọn kò ti Ọlọ́run, pé kí a máa pé òun ni Ọlọ́run wọn; nítorí tí o ti pèsè ìlú kan sílẹ̀ fún wọn.
16 Baise nati efanin i tafaram ta gewasin anababatun hinunuwih, tafaram no maramaim. Isan imih God isan hai God hirouw hio i men biyah eo’ohow. Anayabin hai bar merar gewasin imaim wanatowan ma isan yabuna’ika.
17 Nípa ìgbàgbọ́ ni Abrahamu, nígbà tí a dán an wò láti, fi Isaaki rú ẹbọ: àní òun ẹni tí ó rí ìlérí gba múra tan láti fi ọmọ bíbí rẹ kan ṣoṣo rú ẹbọ.
17 God routobon Abraham bitin ana veya, baitumatumamaim natun ta’imonamo Isaac bai siboromih yai. God ana omatanen Abraham isan i iti na’atube eo,
18 Nípa ẹni tí wí pé, “Nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀.”
18 “O natu Isaac wanawananamaim boro a ub nara’at.” Baise God Abraham rurutubun ana veya Abraham nowarasit.
19 Ó sì rò ó si pé Ọlọ́run tilẹ̀ lè gbé e dìde kúrò nínú òkú, bẹ́ẹ̀ ni, bí a bá sọ ọ́ lọ́nà àpẹẹrẹ, ó gbà á padà.
19 Abraham so’ob Isaac namomorob God karam boro niyawas maiye, naatu ana itinin boro iti na’atube tatao, Abraham natun easabunibo uman botan.
20 Nípa ìgbàgbọ́ ní Isaaki súre fún Jakọbu àti Esau ní ti ohun tí ń bọ̀.
20 Baitumatumamaim Isaac natunatun rou’ab, Jacob, Esau hairi baigegewasin itih, mar boro hai ma gewas isan.
21 Nípa ìgbàgbọ́ ni Jakọbu, nígbà tí o ń ku lọ, ó súre fún àwọn ọmọ Josẹfu ni ọ̀kọ̀ọ̀kan; ó sì sinmi ní ìtẹríba lé orí ọ̀pá rẹ̀.
21 Jacob baitumatumamaim ma’am iregah morobomih ana veya na kakabom auman Joseph natunatun rou’ab igegewasinih. Naatu ana tu’umaim ibais kuso bat God ana merar yi.
22 Nípa ìgbàgbọ́ ni Josẹfu, nígbà tí ó ń ku lọ, ó rántí ìjáde lọ àwọn ọmọ Israẹli; ó sì pàṣẹ ní ti àwọn egungun rẹ̀.
22 Baitumatumamaim Joseph morobomih ana veya na kakabom auman, Israel sabuw Egypt baihamiyin maiye tit isan hai tur eowen, naatu ana rarik auman bai tit isan hai tur eowen.
23 Nípa ìgbàgbọ́ ní àwọn òbí Mose pa a mọ́ fún oṣù mẹ́ta nígbà tí a bí i, nítorí tiwọn rí i ní arẹwà ọmọ; wọn kò sì bẹ̀rù àṣẹ ọba.
23 Baitumatumamaim Moses tutufuw ana veya hinah tamah sumar tounu hibun hima, aiwob orot ana ofafar fokarin eo isan men hibirumih. Anayabin kek tufuw hi’i’itin i men kek afa na’atube’emih.
24 Nípa ìgbàgbọ́ ni Mose, nígbà tí o dàgbà, ó kọ̀ ki a máa pé òun ni ọmọ ọmọbìnrin Farao;
24 Baitumatumamaim Moses ra’at yen orot mamatar ana veya’amaim, i men kok boro Pharaoh natun babitai natun hitarouw hitao.
25 o kúkú yàn láti máa ba àwọn ènìyàn Ọlọ́run jìyà, ju jíjẹ fàájì ẹ̀ṣẹ̀ fún ìgbà díẹ̀.
25 Imih iti yasisir kakafin mar kafai baiyasisir isan i kwahir, naatu God ana sabuw bairi bai’akir isan rubin.
26 Ó ka ẹ̀gàn Kristi si ọrọ̀ tí ó pọ̀jù àwọn ìṣúra Ejibiti lọ, nítorí tí ó ń wo èrè náà.
26 I ana not Keriso wabinamaim sabuw biya’ohow hinitin nabi’akir ana gewasin i ra’at kwanekwan men Egypt wanawan toto buyoy gewasin yomanin en na’atube’emih. Anayabin i ana not etei i ana baiyan boro nan isan yayabuna.
27 Nípa ìgbàgbọ́ ni o kọ Ejibiti sílẹ̀ láìbẹ̀rù ìbínú ọba: nítorí tí o dúró ṣinṣin bí ẹni tí ó n ri ẹni àìrí.
27 Baitumatumamaim Moses misir Egypt ihamiy tit, aiwob orot yan soso’ar isan men bir, baise itafofor tit. Anayabin God wa’iwa’irinamaim ma’am Moses itin.
28 Nípa ìgbàgbọ́ ni ó da àsè ìrékọjá sílẹ̀, àti ìbùwọ́n ẹ̀jẹ̀, kí ẹni tí ń pa àwọn àkọ́bí ọmọ má bá a fi ọwọ́ kan wọn.
28 Baitumatumamaim Moses Tar Nowaten ana bowabow imatar bobaituw hai rara etawan hidadawiren. Saise Gurusenayan kek ai’in rouwamih nanan Israel hai kek ai’in men narouw hinamorob.
29 Nípa ìgbàgbọ́ ni wọn la òkun pupa kọjá bi ẹni pé ni ìyàngbẹ ilẹ̀ ni: ti àwọn ara Ejibiti dánwò, tí wọ́n sì ri.
29 Baitumatumamaim Israel sabuw riy gagamin wabin Red Sea mamah me yanabe hirabon rewan roun hiyen. Baise Egypt baiyowayah hi’ufnunih hirarabon riy matabir maiye re etei himorob.
30 Nípa ìgbàgbọ́ ni àwọn odi Jeriko wo lulẹ̀, lẹ́yìn ìgbà tí a yí wọn ká ni ọjọ́ méje.
30 Baitumatumamaim Israel sabuw veya etei umat roun rou’ab tafaram Jericho bar merar gagamin fur ufun hibiwaibibib ufunamaim fur tafofor re sabuw etei himorob.
31 Nípa ìgbàgbọ́ ni Rahabu panṣágà kò ṣègbé pẹ̀lú àwọn tí kò gbọ́rọ̀ nígbà tí o tẹ́wọ́gbà àwọn àmì ní àlàáfíà.
31 Baitumatumamaim babin ef remorayan wabin Rahab sabuw baifanasairayah hi’a’asbunubunuwen i men hi’asabunimih, anayabin Israel orot rafot rouwayah hinan hai merar yi buwih ana baremaim hirun.
32 Èwo ni èmi o sì tún máa wí sí i? Nítorí pé ìgbà yóò kùnà fún mi láti sọ ti Gideoni, àti Baraki, àti Samsoni, àti Jefta; àti Dafidi, àti Samuẹli, àti ti àwọn wòlíì,
32 Tur i moumurih na’in tema’am baise veya men ema’am boro Gideon, Barak, Samson, Jephthah, David, Samuel naatu dinab oro’orot isah anao kwananowar.
33 àwọn ẹni nípasẹ̀ ìgbàgbọ́ tiwọn ṣẹ́gun ilẹ̀ ọba, tí wọn ṣiṣẹ́ òdodo, tiwọn gba ìlérí, tiwọn dí àwọn kìnnìún lénu,
33 Baitumatumamaim tafaram afa hai aiwob hirouw hinunih, ma gewas ana efamaim sabuw hikaifih bairi hima. Naatu God abisa eomatanih itih, hisinaf lion awah hibit anihimih men hi’anih.
34 tí wọ́n pa agbára iná, tí wọ́n bọ́ lọ́wọ́ ojú idà, tí a sọ di alágbára nínú àìlera, tí wọ́n dí akọni nínú ìjà, wọ́n lé ogun àwọn àjèjì sá.
34 Sabuw ata wairaf in bitakir wan hirouw hiyey men e’arahih, afa kaiy wanane hibihir, afa hiririm hi’inu’in hai fair hibai maiye, afa ahay waf wanawanan hirun nah hi’aiseyasey hibat rakit hi’abargiyigiyih.
35 Àwọn obìnrin ri òkú wọn gbà nípa àjíǹde: a sì da àwọn ẹlòmíràn lóró, wọ́n kọ̀ láti gba ìdásílẹ̀; kí wọn ba lè rí àjíǹde tí o dára jù gbà.
35 Baibin afa taih tuwah morobone God iyawasih itih, afa morob hirubin God hibitumitum isan rakit himisir hibow hirouw biyah hibeyat, biyababan bai’akir gagamin maiyow hibai. Anayabin i hiso’ob morobone misir maiye isan i boro gewasinamaim hinamisir maiye.
36 Àwọn ẹlòmíràn sì rí ìjìyà ẹ̀sín, àti nínà, àti ju bẹ́ẹ̀ lọ, ti ìdè àti ti túbú.
36 Afa hi’iyabih hi’uwih kwanikwaniyih naatu hibow hirouw biyah hikwimih, afa hibow hifatumih hin dibur hiya.
37 A sọ wọ́n ni òkúta, a fi ayùn rẹ́ wọn sì méjì, a dán wọn wò a fi idà pa wọn, wọ́n rìn káàkiri nínú awọ àgùntàn àti nínú awọ ewúrẹ́; wọn di aláìní, olùpọ́njú, ẹni tí a ń da lóró;
37 Afa kabayamaim hirouw himorob, afa naiwah so’omaim hiboro’omen, afa kaiyomaim hiyow himorob, afa bai’akir gagamin maiyow hibai, sheep, goat, bunibunihimaim ar faifuw hisakir hiyon, yababan hibai aurih sawar i’en, aa murumurubih hi’a’akir naatu hirukoukuwih hima hiremor.
38 àwọn ẹni tí ayé ko yẹ fún. Wọ́n ń kiri nínú aṣálẹ̀, àti lórí òkè, àti nínú ihò àti nínú abẹ́ ilẹ̀.
38 Iti tafaramamaim hai ma isan i men igewasin, sabuw toumanih na’atube arar yan, oyaw an, watu wanawanan, sou wanawanan imaim hi’in hima hiremor.
39 Gbogbo àwọn wọ̀nyí tí a jẹ́rìí rere sí nípa ìgbàgbọ́, wọn kò sì rí ìlérí náà gbà,
39 Sabuw iti etei i hai baitumatumamaim wabih iti tema’am, baise sawar abisa God eo’omatanih men yait ta bai.
40 nítorí Ọlọ́run ti pèsè ohun tí ó dára jù sílẹ̀ fún wa, pé láìsí wa, kí a má ṣe wọn pé.
40 Anayabin God ana kok nati sabuw i boro hinama hinakaif saise it bairit auta’imon nati sawar gewasin nafaramit youn.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Hebreus 11, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.