Gênesis 36
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Wọ̀nyí ni ìran Esau, ẹni tí a ń pè ní Edomu.
1 Ora, estas são as gerações de Esaú, que é Edom.
2 Nínú àwọn ọmọbìnrin Kenaani ni Esau ti fẹ́ àwọn ìyàwó rẹ̀: Adah ọmọbìnrin Eloni ará Hiti àti Oholibama, ọmọbìnrin Ana, ọmọ ọmọ Sibeoni ará Hifi.
2 Esaú tomou suas mulheres das filhas de Canaã: Ada, filha de Elom, heteu; Aolibama, filha de Aná, filho de Zibeão, heveu;
3 Ó sì tún fẹ́ Basemati ọmọ Iṣmaeli arábìnrin Nebaioti.
3 e Basemate, filha de Ismael, irmã de Nebaiote.
4 Adah bí Elifasi fún Esau, Basemati sì bí Reueli,
4 E Ada gerou de Esaú a Elifaz; e Basemate gerou Reuel;
5 Oholibama pẹ̀lú sì bí Jeuṣi, Jalamu, àti Kora. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ tí Esau bí ní Kenaani.
5 e Aolibama gerou Jeús, e Jalão, e Corá; estes são os filhos de Esaú, que lhe nasceram na terra de Canaã.
6 Esau sì mú àwọn aya rẹ̀, àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, àwọn ọmọbìnrin rẹ̀ àti gbogbo àwọn ará ilé rẹ̀, àwọn ohun ọ̀sìn rẹ̀ àti àwọn ẹran ọ̀sìn mìíràn àti gbogbo ohun ìní mìíràn tí ó ní, ni Kenaani, ó sì kó lọ sí ilẹ̀ mìíràn, jìnà sí ibi tí Jakọbu arákùnrin rẹ̀ wà.
6 E Esaú tomou suas mulheres, e seus filhos, e suas filhas, e todas as pessoas de sua casa, e seu gado, e todos os seus animais, e todos os seus bens, que ele havia obtido na terra de Canaã, e foi para outra terra, afastando-se da face de seu irmão Jacó.
7 Ohun ìní wọn pọ̀ ju èyí tí àwọn méjèèjì lè máa gbé ní ojú kan lọ. Ilẹ̀ tí wọ́n wà kò le gba àwọn méjèèjì nítorí àwọn ohun ọ̀sìn wọn.
7 Porque as suas riquezas eram demais para que eles pudessem habitar juntos, e a terra em que eles eram estrangeiros não podia sustentá-los por causa de seu gado.
8 Báyìí ni Esau (tí a tún mọ̀ sí Edomu) tẹ̀dó sí àwọn orílẹ̀-èdè olókè tí Seiri.
8 Assim, Esaú habitou no monte Seir; Esaú é Edom.
9 Èyí ni ìran Esau baba àwọn ará Edomu ní àwọn orílẹ̀-èdè olókè Seiri.
9 E estas são as gerações de Esaú, pai dos edomitas, no monte Seir;
10 Wọ̀nyí ni orúkọ àwọn ọmọ Esau:
10 Estes são os nomes dos filhos de Esaú: Elifaz, filho de Ada, mulher de Esaú; Reuel, filho de Basemate, mulher de Esaú.
11 Àwọn ọmọ Elifasi ni ìwọ̀nyí:
11 E os filhos de Elifaz foram: Temã, Omar, Zefô, Gaetã e Quenaz.
12 Elifasi ọmọ Esau sì tún ní àlè tí a ń pè ní Timna pẹ̀lú, òun ló bí Amaleki fún un. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ ọmọ Adah aya Esau.
12 E Timna era concubina de Elifaz, filho de Esaú, e gerou de Elifaz a Amaleque; estes são os filhos de Ada, mulher de Esaú.
13 Àwọn ọmọ Reueli:
13 E estes são os filhos de Reuel: Naate, Zerá, Samá e Mizá; estes foram os filhos de Basemate, mulher de Esaú.
14 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Oholibama ọmọbìnrin Ana ọmọ ọmọ Sibeoni: tí ó bí fún Esau:
14 E estes foram os filhos de Aolibama, filha de Aná, filho de Zibeão, mulher de Esaú; e ela gerou a Esaú: Jeús, Jalão e Corá.
15 Àwọn wọ̀nyí ni olórí nínú àwọn ọmọ Esau:
15 Estes são os xeiques dos filhos de Esaú; os filhos de Elifaz, o filho primogênito de Esaú: o xeique Temã, o xeique Omar, o xeique Zefô, o xeique Quenaz,
16 Kora, Gatamu àti Amaleki. Àwọn wọ̀nyí ló jẹ́ olórí ìdílé tí ó ti ọ̀dọ̀ Elifasi ní Edomu wá, wọ́n jẹ́ ọmọ ọmọ Adah.
16 o xeique Corá, o xeique Gaetã, e o xeique Amaleque; estes são os xeiques que vieram de Elifaz, na terra de Edom; estes foram os filhos de Ada.
17 Wọ̀nyí sì ni àwọn ọmọ Esau, ọmọ Rueli:
17 E estes são os filhos de Reuel, filho de Esaú: o xeique Naate, o xeique Zerá, o xeique Samá, o xeique Mizá; estes são os xeiques que vieram de Reuel, na terra de Edom; estes são os filhos de Basemate, mulher de Esaú.
18 Àwọn ọmọ Oholibama aya Esau:
18 E estes são os filhos de Aolibama, mulher de Esaú: o xeique Jeús, o xeique Jalão, o xeique Corá; estes são os xeiques que vieram de Aolibama, filha de Aná, mulher de Esaú.
19 Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Esau (ti o túmọ̀ sí Edomu). Àwọn wọ̀nyí ni olórí wọn.
19 Estes são os filhos de Esaú, que é Edom, e estes são os seus xeiques.
20 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Seiri ará Hori tí ó ń gbé ní ilẹ̀ náà:
20 Estes são os filhos de Seir, horeu, que habitava a terra: Lotã, Sobal, Zibeão, e Aná,
21 Diṣoni, Eseri, àti Diṣani, àwọn wọ̀nyí olórí ènìyàn Hori, àwọn ọmọ Seiri ni ilẹ̀ Edomu.
21 e Disom, e Eser, e Disã; estes são os xeiques dos horeus, filhos de Seir, na terra de Edom.
22 Àwọn ọmọ Lotani:
22 E os filhos de Lotã foram: Hori e Homã; e a irmã de Lotã era Timna.
23 Àwọn ọmọ Ṣobali:
23 E os filhos de Sobal foram estes: Alvã, e Manaate, e Ebal, Sefô e Onã.
24 Àwọn ọmọ Sibeoni:
24 E estes são os filhos de Zibeão: Aías e Aná; este é o Aná que achou as mulas no deserto, quando ele alimentava os jumentos de Zibeão, seu pai.
25 Wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Ana:
25 E os filhos de Aná são esses: Disom e Aolibama, a filha de Aná.
26 Àwọn ọmọ Diṣoni ni:
26 E estes são os filhos de Disom: Hendã, Esbã, Itrã e Querã.
27 Àwọn ọmọ Eseri:
27 Os filhos de Eser são esses: Bilã, Zaavã e Acã.
28 Àwọn ọmọ Diṣani ni:
28 Os filhos de Disã são esses: Uz e Arã.
29 Àwọn wọ̀nyí ni olórí ìdílé Hori:
29 Estes são os xeiques que vieram dos horeus: o xeique Lotã, o xeique Sobal, o xeique Zibeão, o xeique Aná,
30 Diṣoni Eseri, àti Diṣani.
30 o xeique Disom, o xeique Eser, o xeique Disã; estes são os xeiques que vieram de Hori, segundo seus xeiques, na terra de Seir.
31 Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Edomu kí ó tó di pé ọba kankan jẹ lórí Israẹli:
31 E estes são os reis que reinaram na terra de Edom, antes que reinasse algum rei sobre os filhos de Israel.
32 Bela ọmọ Beori jẹ ní Edomu. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Dinhaba.
32 E Bela, filho de Beor, reinou em Edom; e o nome da sua cidade foi Dinabá.
33 Nígbà tí Bela kú, Jobabu ọmọ Sera ti Bosra sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
33 E morreu Bela; e Jobabe, filho de Zerá, de Bozra, reinou em seu lugar.
34 Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu láti ilẹ̀ Temani sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
34 E morreu Jobabe; e Husão, da terra de Temã, reinou em seu lugar.
35 Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi ọmọ Bedadi tí ó kọlu Midiani ní ìgbẹ́ Moabu, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.
35 E morreu Husão, e em seu lugar reinou Hadade, filho de Bedade, o que feriu Midiã no campo de Moabe; e o nome da sua cidade foi Avite.
36 Nígbà tí Hadadi sì kú, Samla láti Masreka, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
36 E morreu Hadade; e Samlá, de Masreca, reinou em seu lugar.
37 Samla sì kú, Saulu ti Rehoboti, létí odò sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
37 E morreu Samlá; e Saul, de Reobote junto ao rio, reinou em seu lugar.
38 Nígbà tí Saulu kú, Baali-Hanani ọmọ Akbori jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
38 E morreu Saul; e Baal-Hanã, filho de Acbor, reinou em seu lugar.
39 Nígbà tí Baali-Hanani ọmọ Akbori kú, Hadadi ni ó jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau, orúkọ ìyàwó sì ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu.
39 E Baal-Hanã, filho de Acbor, morreu; e Hadar reinou em seu lugar; e o nome da sua cidade foi Paú; e o nome de sua mulher foi Meetabel, filha de Matrede, filha de Me-Zaabe.
40 Àwọn wọ̀nyí ni orúkọ àwọn baálẹ̀ tí ó ti ọ̀dọ̀ Esau jáde wá, ní orúkọ ìdílé wọn, bí ìpínlẹ̀ wọn ti rí:
40 E estes são os nomes dos xeiques que vieram de Esaú, segundo as suas famílias, segundo os seus lugares, pelos seus nomes: o xeique Timna, o xeique Alva, o xeique Jetete,
41 Baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni,
41 o xeique Aolibama, o xeique Elá, o xeique Pinom,
42 baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari,
42 o xeique Quenaz, o xeique Temã, o xeique Mibzar,
43 Magdieli, àti Iramu.
43 o xeique Magdiel, o xeique Irã; estes são os xeiques de Edom, de acordo com as suas habitações na terra da sua possessão; este é Esaú, pai dos edomitas.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Gênesis 36, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.