Ezequiel 5
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 “Báyìí, ọmọ ènìyàn, mú ìdá tí ó mú kí o sì fi ṣe abẹ ìfárí onígbàjámọ̀, kí o fi fá irun orí àti irùngbọ̀n rẹ. Fi irun yìí sórí ìwọ̀n kí o sì pín in.
1 E tu, filho do homem, toma uma faca afiada, toma uma navalha de barbeiro, e faze-a passar sobre a tua cabeça e sobre a tua barba; então toma uma balança de pesar, e divide o cabelo.
2 Nígbà tí ọjọ́ ìgbóguntì bá parí, sun ìdákan nínú ìdámẹ́ta irun yìí níná láàrín ìlú. Mú ìdákan nínú mẹ́ta kí o fi idà bù ú káàkiri ìlú. Kí o sì tú ìdákan yòókù ká sínú afẹ́fẹ́. Nítorí pé pẹ̀lú idà ni èmi yóò máa lé wọn ká.
2 Tu queimarás com fogo uma terça parte, no meio da cidade, quando os dias do cerco se cumprirem; e tu tomarás uma terça parte, e feri-la-ás ao redor com uma faca; e uma terça parte espalharás ao vento; e eu desembainharei uma espada atrás deles.
3 Ṣùgbọ́n mú díẹ̀ nínú irun yìí kí o sì ta á mọ́ etí aṣọ rẹ.
3 Tu também tomarás dali um pequeno número, e atá-los-ás às tuas saias.
4 Tún ju díẹ̀ nínú irun yìí sínú iná, kí o sun ún níná. Torí pé láti ibẹ̀ ni iná yóò ti jáde lọ sí gbogbo ilé Israẹli.
4 Então, toma deles novamente e lança-os no meio do fogo, e queima-os no fogo; pois dali sairá um fogo que entrará em toda a casa de Israel.
5 “Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èyí ní Jerusalẹmu, tí mo gbé kalẹ̀ sí àárín àwọn Orílẹ̀-èdè, pẹ̀lú àwọn ìlú gbogbo tí o yí i ká.
5 Assim diz o Senhor DEUS: Esta é Jerusalém; eu a coloquei no meio das nações e das terras que estão ao redor dela.
6 Síbẹ̀ nínú ìwà búburú rẹ ó ti ṣọ̀tẹ̀ si òfin àti ìlànà mi ju àwọn orílẹ̀-èdè àti àwọn ilẹ̀ tó yí i ká lọ. Ó ti kọ òfin mi sílẹ̀, o kò sì pa ìlànà mi mọ́.
6 E ela mudou os meus juízos em perversidade, mais do que as nações, e os meus estatutos mais do que os países que estão ao redor dela; porque rejeitaram os meus juízos e os meus estatutos, e não andaram neles.
7 “Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Nítorí pé ẹ̀yin ti ṣe àìgbọ́ràn ju àwọn orílẹ̀-èdè tó yí yín ká lọ, tí ẹ kò sì tẹ̀lé ìlànà mi tàbí kí o pa òfin mi mọ́. O kò tilẹ̀ túnṣe dáradára tó àwọn orílẹ̀-èdè tó yí ọ ká.
7 Portanto, assim diz o Senhor DEUS: Porque multiplicastes mais do que as nações que estão ao redor de vós, e não andastes nos meus estatutos, nem guardastes os meus juízos, nem fizestes de acordo com os juízos das nações que estão ao redor de vós.
8 “Nítorí náà báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi gan an lòdì sí ọ, Jerusalẹmu, èmi yóò sì jẹ ọ́ ní yà lójú àwọn orílẹ̀-èdè tó yí ọ ká.
8 Portanto, assim diz o Senhor DEUS: Eis que eu, eu mesmo, estou contra ti; e executarei juízos no meio de ti à vista das nações.
9 Nítorí gbogbo ohun ìríra rẹ, èmi yóò ṣe ohun tí n kò tí ì ṣe rí láàrín rẹ àti èyí tí n kò ní í ṣe irú rẹ̀ mọ́.
9 E eu farei contigo o que nunca fiz, nem voltarei a fazer coisa semelhante, por causa de todas as tuas abominações.
10 Nítorí náà láàrín rẹ àwọn baba yóò máa jẹ ọmọ wọn, àwọn ọmọ náà yóò máa jẹ baba wọn. Èmi yóò jẹ ọ́ ní yà, èmi yóò sì tú àwọn tó bá ṣẹ́kù ká sínú ẹ̀fúùfù.
10 Portanto, os pais comerão a seus filhos no meio de ti, e os filhos comerão a seus pais; e eu executarei juízos em ti, e a todos os teus remanescentes, eu espalharei a todos os ventos.
11 Nítorí náà, Olúwa Olódùmarè wí pé, bí mo ṣe wà láààyè, nítorí pé ìwọ ti sọ ibi mímọ́ mi di àìmọ́ pẹ̀lú àwọn àwòrán ẹ̀gbin àti àwọn ohun ìríra rẹ, èmi yóò mú ojúrere mi kúrò lára rẹ, èmi kò ní í da ọ sí, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò wò ọ́ pẹ̀lú àánú mọ́.
11 Portanto, como eu vivo, diz o Senhor DEUS; certamente, porque tens contaminado o meu santuário com todas as tuas coisas detestáveis, e com todas as tuas abominações, por isso, eu também te diminuirei; nem meu olho poupará, nem terei pena alguma.
12 Ìdámẹ́ta nínú àwọn ènìyàn rẹ yóò kú nípa àjàkálẹ̀-ààrùn tàbí kí ìyàn run wọ́n: ìdámẹ́ta yóò ṣubú nípa idà lẹ́yìn odi rẹ, èmi yóò sì tú ìdámẹ́ta yòókù ká sínú ẹ̀fúùfù, èmi yóò sì máa fi idà lé wọn.
12 Uma terça parte de ti morrerá com a peste, e com fome será consumida no meio de ti; e uma terça parte cairá pela espada ao redor de ti; e eu espalharei uma terça parte a todos os ventos, e desembainharei a espada atrás deles.
13 “Ìbínú mi yóò sì dúró, bẹ́ẹ̀ ni ìbínú gbígbóná mi yóò sì rọlẹ̀, èmi yóò sì ti gba ẹ̀san mi. Nígbà tí mo bá sì parí ìbínú mi lórí wọn, wọn ó mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀ nínú ìtara mi.
13 Assim, minha ira se cumprirá, e eu farei minha fúria descansar sobre eles, e me consolarei; e saberão que eu, o SENHOR, tenho falado isso no meu zelo, quando eu tiver cumprido a minha fúria neles.
14 “Èmi yóò fi ọ́ ṣòfò, èmi yóò sì sọ ọ́ di ẹ̀gàn fún àwọn orílẹ̀-èdè tó yí ọ ká, àti lójú àwọn tó ń kọjá.
14 Além disso, eu farei de ti lixo e vergonha entre as nações que estão ao redor de ti, à vista de todos os que passarem.
15 O ó wá di ẹ̀gàn, ẹ̀sín àti ẹ̀kọ̀ àti ohun ẹ̀rù àti ìyanu fún àwọn orílẹ̀-èdè tó yí ọ ká, nígbà tí mo bá fìyà jẹ ọ́ nínú ìbínú àti nínú ìbínú gbígbóná mi. Èmi Olúwa ni ó sọ bẹ́ẹ̀.
15 Então ele será uma vergonha e um escárnio, uma instrução e um espanto às nações que estão ao redor de ti, quando eu executar juízos em ti, na ira, e na fúria, e com repreensões furiosas. Eu, o SENHOR, tenho falado isso.
16 Nígbà tí èmi ó rán ọfà búburú ìyàn sí wọn, èyí tí yóò jẹ́ fún ìparun wọn. Èmí tí èmi yóò rán run yín. Èmí yóò sì sọ ìyàn di púpọ̀ fún yín. Èmí yóò sì ṣẹ́ ọ̀pá oúnjẹ yín.
16 Quando eu enviar sobre eles as malignas flechas da fome, que servirão para destruição deles, e as quais eu enviarei para vos destruir; e aumentarei a fome sobre vós, e vos quebrarei o báculo do pão.
17 Èmi yóò rán ìyàn àti ẹranko búburú sí i yín, wọn yóò fi yín sílẹ̀ ni àìlọ́mọ. Àjàkálẹ̀-ààrùn àti ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò kọjá láàrín yín. Èmi yóò si mú idà wá sórí rẹ. Èmi Olúwa ló sọ bẹ́ẹ̀.”
17 Assim eu enviarei sobre vós a fome, e animais malignos, e eles te desolarão; e peste e sangue passarão por ti; e trarei a espada sobre ti. Eu, o SENHOR, tenho falado isso.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Ezequiel 5, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.