Ezequiel 32
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kejìlá, ọdún kejìlá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
1 E sucedeu que, no ano duodécimo, no duodécimo mês, no primeiro dia do mês, a palavra do SENHOR veio a mim, dizendo:
2 “Ọmọ ènìyàn, ṣe ìpohùnréré ẹkún nítorí Farao ọba Ejibiti kí o sì wí fún un:
2 Filho do homem, levanta uma lamentação sobre Faraó, rei do Egito, e dize-lhe: Tu és semelhante a um leão jovem das nações, e tu és como uma baleia nos mares, e tu vens adiante com os teus rios, e atribulaste as águas com os teus pés, e sujastes os seus rios.
3 “ ‘Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí:
3 Assim diz o Senhor DEUS: Portanto, eu estenderei a minha rede sobre ti com a companhia de muitas pessoas, e elas te trarão em minha rede.
4 Èmi yóò jù ọ́ sí orí ilẹ̀
4 Então, eu te deixarei sobre a terra; lançar-te-ei adiante sobre o campo aberto, e farei com que as aves do céu permaneçam sobre ti, e preencherei os animais de toda a terra contigo.
5 Èmi yóò tan ẹran-ara rẹ ká sórí
5 E eu deitarei a tua carne sobre os montes, e encherei os vales com a tua altura.
6 Ẹ̀jẹ̀ rẹ ti ń sàn ní èmi yóò sì fi rin ilẹ̀ náà
6 E eu também regarei com o teu sangue a terra onde tu nadas, até aos montes; e os rios se encherão de ti.
7 Nígbà tí mo bá fọ́n ọ jáde, èmi yóò pa ọ̀run dé
7 E quando eu te extinguir, cobrirei o céu, e farei suas estrelas escuras; eu cobrirei o sol com a nuvem, e a lua não dará a sua luz.
8 Gbogbo ìmọ́lẹ̀ títàn ní ojú ọ̀run
8 Todas as luzes brilhantes do céu tornarei escuras sobre ti, e estabelecerei trevas sobre a tua terra, diz o Senhor DEUS.
9 Èmi yóò da ọkàn ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn rú
9 E aborrecerei os corações de muitas pessoas, quando eu trouxer a tua destruição entre as nações, nos países que tu não conheceste.
10 Èmi yóò mú kí ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn dẹ́rùbà ọ́,
10 Sim, eu farei com que muitos povos fiquem espantados contigo, e seus reis ficarão horrivelmente temerosos por ti, quando eu brandir a minha espada diante deles; e eles tremerão a cada momento, cada homem por sua própria vida, no dia da tua queda.
11 “ ‘Nítorí èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí:
11 Porque assim diz o Senhor DEUS: A espada do rei de Babilônia virá sobre ti.
12 Èmi yóò mú kí ìjọ ènìyàn rẹ kí ó
12 Pelas espadas dos poderosos eu farei a tua multidão cair, os terríveis das nações, todos eles; e eles despojarão a pompa do Egito, e toda a sua multidão será destruída.
13 Gbogbo ẹran ọ̀sìn rẹ ni èmi yóò parun
13 Do lado das grandes águas eu destruirei também todos os seus animais; nem o pé do homem os atribulará mais, nem os cascos dos animais os atribularão.
14 Lẹ́yìn náà èmi yóò mú kí omi rẹ̀ tòrò
14 Então, eu farei suas águas profundas, e farei com que seus rios corram como o azeite, diz o Senhor DEUS.
15 Nígbà tí mo bá sọ Ejibiti di ahoro,
15 Quando eu tornar a terra do Egito assolada, e o país estiver destituído daquilo que estava cheio; quando eu ferir todos aqueles que habitam lá, então eles saberão que eu sou o SENHOR.
16 “Èyí yìí ni ẹkún tí a yóò sun fún un. Àwọn ọmọbìnrin orílẹ̀-èdè yóò sun ún; nítorí Ejibiti àti gbogbo ìjọ rẹ, wọn yóò sun ún, ní Olúwa Olódùmarè wí.”
16 Esta é a lamentação com a qual a lamentarão; as filhas das nações a lamentarão; elas lamentarão por ela, até mesmo pelo Egito, e por toda a sua multidão, diz o Senhor DEUS.
17 Ní ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù, ọdún kejìlá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ mí wá:
17 E sucedeu também que, no ano duodécimo, no décimo quinto dia do mês, a palavra do SENHOR veio a mim, dizendo:
18 “Ọmọ ènìyàn, pohùnréré ẹkún lórí Ejibiti kí o sì ránṣẹ́ sí ìsàlẹ̀ ilẹ̀ àti òun àti àwọn ọmọbìnrin orílẹ̀-èdè alágbára, pẹ̀lú àwọn tí o lọ sí ìsàlẹ̀, kòtò.
18 Filho do homem, lamenta para a multidão do Egito, e faze-a descer, a ela e as filhas das nações famosas até as partes baixas da terra, com aquelas que descem à cova.
19 Sọ fún wọn, ‘Ǹjẹ́ ìwọ ní ojúrere jù àwọn tí o kù lọ? Lọ sí ìsàlẹ̀ kí a sì tẹ́ ọ sí àárín àwọn aláìkọlà náà.’
19 A quem passas tu em formosura? Desce, e deita-te com os incircuncisos.
20 Wọn yóò ṣubú láàrín àwọn tí a fi idà pa. A fa idà yọ; jẹ́ kí a wọ́ Ejibiti kúrò pẹ̀lú gbogbo ìjọ rẹ̀.
20 No meio daqueles que são mortos à espada elas cairão, à espada ela está entregue; arrastai-a e a toda a sua multidão.
21 Láti inú isà òkú alágbára tí í ṣe aṣáájú yóò sọ nípa Ejibiti àti àwọn àlejò rẹ̀, ‘Wọn ti wá sí ìsàlẹ̀, wọn sì sùn pẹ̀lú aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa.’
21 Os fortes entre os poderosos falarão desde o meio do inferno, com aqueles que o ajudam; eles já desceram, e jazem incircuncisos, mortos pela espada.
22 “Asiria wà níbẹ̀ pẹ̀lú gbogbo jagunjagun rẹ̀; àwọn isà òkú àwọn tí a ti pa sì yí i ká, gbogbo àwọn tí ó ti ipa idà ṣubú.
22 Assur está lá e toda a sua companhia; seus túmulos estão ao redor dele; todos eles mortos, abatidos à espada.
23 Isà òkú wọn wà ní ibi tí ó jinlẹ̀ gan an nínú kòtò. Gbogbo àwọn tí ó ti tan ẹ̀rù ká ilẹ̀ alààyè ní a pa, tí ó ti ipa idà ṣubú.
23 Cujos túmulos estão estabelecidos nos lados da cova, e sua companhia está ao redor de seu túmulo; todos eles mortos, abatidos à espada, o que causou terror na terra dos vivos.
24 “Elamu wà níbẹ̀, o yí isà òkú rẹ̀ ká pẹ̀lú gbogbo ogun rẹ̀. Gbogbo wọn ni a pa, àwọn tí ó ti ipa idà ṣubú. Gbogbo àwọn tí ó ti tan ẹ̀rù ká ilẹ̀ alààyè lọ sí ìsàlẹ̀ láìkọlà sí abẹ́ ilẹ̀. Wọ́n gba ìtìjú wọn pẹ̀lú àwọn tí ó lọ sí ìsàlẹ̀ kòtò.
24 Ali está Elão e toda a sua multidão ao redor do seu sepulcro; todos eles mortos, abatidos à espada; que desceram incircuncisos às partes baixas da terra, o que causou terror na terra dos vivos, e carregaram a sua vergonha com aqueles que descem à cova.
25 A ṣe ibùsùn fún un láàrín àwọn tí a pa, pẹ̀lú gbogbo ìjọ rẹ̀ tí ó yí isà òkú ká. Gbogbo wọn jẹ́ aláìkọlà, tí a fi idà pa. Nítorí pé a tan ẹ̀rù wọn ká ilẹ̀ alààyè, wọn ru ìtìjú wọn pẹ̀lú àwọn tí ó lọ sí ìsàlẹ̀ kòtò; a tẹ́ wọn pẹ̀lú àwọn tí a pa.
25 Então, puseram-lhe uma cama no meio dos mortos com toda a sua multidão; seus túmulos estão ao redor dele; todos os incircuncisos, mortos à espada, embora o seu terror fosse causado na terra dos vivos, ainda assim eles carregaram sua vergonha com aqueles que descem à cova; ele é colocado no meio daqueles que são mortos.
26 “Meṣeki àti Tubali wà níbẹ̀, pẹ̀lú gbogbo ogun wọn yí isà òkú wọn ká. Gbogbo wọn jẹ́ aláìkọlà, wọ́n fi idà pa wọ́n nítorí ẹ̀rù tiwọn tàn ká ilẹ̀ alààyè.
26 Ali estão Meseque, Tubal e toda a sua multidão; seus túmulos estão ao redor dele; todos eles incircuncisos, mortos à espada, embora tenham causado o seu terror na terra dos vivos.
27 Wọn kì yóò sì dùbúlẹ̀ ti àwọn tí ó ṣubú nínú àwọn aláìkọlà, tí wọn sọ̀kalẹ̀ lọ sí ipò òkú pẹ̀lú ìhámọ́ra ogun wọn, wọ́n tí fi idà wọn rọ orí wọn. Ṣùgbọ́n àìṣedéédéé wọn yóò wà ní orí egungun wọn—bí wọ́n tilẹ̀ jẹ́ ẹ̀rù àwọn alágbára ní ilẹ̀ alààyè.
27 E eles não jazerão com os poderosos que estão caídos por causa dos incircuncisos, que desceram ao inferno com as suas armas de guerra, e puseram as suas espadas debaixo das suas cabeças; mas suas iniquidades estarão sobre os seus ossos, embora eles fossem o terror dos poderosos na terra dos vivos.
28 “Ìwọ náà, Farao, ní yóò ṣẹ, ti yóò dùbúlẹ̀ láàrín aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa.
28 Sim, tu serás quebrado no meio dos incircuncisos, e jazerás com aqueles que são mortos pela espada.
29 “Edomu wà níbẹ̀, àwọn ọba rẹ̀ àti gbogbo ọmọbìnrin ọba; bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ní agbára, a tẹ́ wọn pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa. Wọn dùbúlẹ̀ pẹ̀lú aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn ti o lọ sínú kòtò.
29 Ali está Edom, os seus reis e todos os seus príncipes, que com o seu poder são postos ao lado dos que foram mortos pela espada; estes jazerão com os incircuncisos e com os que descem à cova.
30 “Gbogbo àwọn ọmọ-aládé ilẹ̀ àríwá àti gbogbo àwọn ará Sidoni wà níbẹ̀; wọn lọ sí ìsàlẹ̀ pẹ̀lú àwọn tí a pa ní ìtìjú, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọn ṣe okùnfà ẹ̀rù pẹ̀lú agbára wọn. Wọn sùn ní àìkọlà pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa, wọn sì ru ìtìjú wọn pẹ̀lú àwọn tí ó lọ sí ìsàlẹ̀ kòtò.
30 Ali estão os príncipes do norte, todos eles, e todos os sidônios, que desceram com os mortos, com o seu terror eles são envergonhados pelo seu poder; e jazem incircuncisos com os que são mortos pela espada, e carregam a sua vergonha com os que descem à cova.
31 “Farao, òun àti gbogbo jagunjagun rẹ̀ yóò rí wọn, a yóò sì tù ú nínú nítorí gbogbo ogun rẹ̀ tí a fi idà pa, ní Olúwa Olódùmarè wí.
31 Faraó os verá, e será consolado com toda a sua multidão; Faraó, e todo o seu exército, mortos pela espada, diz o Senhor DEUS.
32 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti tan ẹ̀rù ká ilẹ̀ alààyè, Farao àti gbogbo ogun rẹ̀ ni a yóò tẹ́ sí àárín aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa ní Olúwa Olódùmarè wí.”
32 Porque eu causei meu terror na terra dos vivos; e ele jazerá no meio dos incircuncisos, com os que são mortos pela espada, Faraó e toda a sua multidão, diz o Senhor DEUS.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Ezequiel 32, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.