Ezequiel 31

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH

Sair da comparação
NTLH Nova Tradução na Linguagem de Hoje 2000
1 Ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kẹta ọdún kọkànlá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
1 No ano décimo primeiro do nosso cativeiro , no dia primeiro do terceiro mês , o Senhor falou comigo. Ele disse:
2 “Ọmọ ènìyàn, sọ fún Farao ọba Ejibiti àti sí ìjọ rẹ̀:
2 — Homem mortal , diga o seguinte ao rei do Egito e a todo o seu povo: “Como você é poderoso! Com o que posso compará-lo?
3 Kíyèsi Asiria, tí ó jẹ́ igi kedari ni
3 Você é como um cedro no Líbano, com galhos lindos, cheios de folhas, uma árvore tão alta, que chega até as nuvens.
4 Omi mú un dàgbàsókè:
4 Havia água para fazê-lo crescer e rios debaixo da terra para alimentá-lo. Regaram o lugar onde a árvore estava crescendo e fizeram com que ribeirões regassem todas as árvores da floresta.
5 Nítorí náà ó ga sí òkè fíofío
5 Por ter sido bem-regado, o cedro cresceu mais do que as outras árvores, e os seus galhos ficaram grossos e compridos.
6 Ẹyẹ ojú ọ̀run
6 Aves de todo tipo faziam ninhos nos seus galhos; embaixo dele, os animais ferozes davam cria, e na sua sombra as nações do mundo descansavam.
7 Ọláńlá ní ẹwà rẹ̀ jẹ́,
7 Como era linda aquela árvore, tão alta e com galhos tão compridos! As suas raízes chegavam até as correntezas profundas.
8 Àwọn igi kedari nínú ọgbà Ọlọ́run
8 Nenhum cedro no jardim de Deus podia comparar-se com ela, nenhum cipreste teve galhos assim, e nenhuma figueira brava teve ramos iguais aos dela. Nenhuma árvore no jardim de Deus foi tão linda como aquela.
9 Mo mú kí ó ní ẹwà
9 Eu a fiz linda assim e cheia de muitos galhos. No Éden, o jardim de Deus, todas as árvores a invejavam.”
10 “ ‘Nítorí náà, èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Nítorí pé ó ga lọ sókè fíofío, tí ó sì gbé òkè rẹ̀ ga ju ewé tí ó nípọn lọ, àti nítorí pé gíga rẹ mú kí ó gbéraga,
10 — Agora, eu, o Senhor Deus, direi a vocês o que vai acontecer. A árvore cresceu tanto, que chegou até as nuvens; mas, conforme crescia, também aumentava o seu orgulho.
11 mo fi lé alákòóso àwọn orílẹ̀-èdè náà lọ́wọ́, fún un láti fi ṣe ẹ̀tọ́ fún un gẹ́gẹ́ bí ìwà búburú rẹ̀. Mo pa á tì sí ẹ̀gbẹ́ kan,
11 Por isso, rejeitei a árvore e vou deixar que um rei estrangeiro a conquiste. Ele dará a ela o tratamento que a sua maldade merece.
12 àwọn orílẹ̀-èdè àjèjì aláìláàánú jùlọ ké e lulẹ̀, wọn sì fi kalẹ̀. Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ ṣubú sórí òkè àti sí gbogbo àárín àwọn òkè; àwọn ẹ̀ka rẹ̀ tí ó ṣẹ nà sílẹ̀ ní gbogbo àlàfo jíjìn ilẹ̀. Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ilẹ̀ ayé jáde kúrò ní abẹ́ ìji rẹ̀ wọn sì fi sílẹ̀.
12 Estrangeiros cruéis a derrubarão e a abandonarão. Os seus galhos e ramos quebrados cairão em todos os vales e em todas as montanhas do país. Todas as nações que viveram embaixo da sua sombra irão embora.
13 Gbogbo àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run ṣe àtìpó ni orí igi tí ó ṣubú lulẹ̀ náà, gbogbo àwọn ẹranko igbó wà ní àárín ẹ̀ka rẹ̀.
13 Os pássaros pousarão na árvore caída, e os animais ferozes andarão por cima dos seus galhos.
14 Nítorí náà kò sí igi mìíràn lẹ́gbẹ̀ẹ́ omi tí ó lè fi ìgbéraga ga sókè fíofío, tí yóò sì gbé sókè rẹ̀ ga ju ewé tí ó nípọn lọ. Kò sí igi mìíràn tí ó ní omi tó bẹ́ẹ̀ tí ó lè ga tó bẹ́ẹ̀; gbogbo wọn ni a kádàrá ikú fún, fún ìsàlẹ̀ ilẹ̀, ní àárín àwọn alààyè ènìyàn, pẹ̀lú àwọn tí o lọ sí ọ̀gbun ní ìsàlẹ̀.
14 E assim, daqui em diante, nenhuma árvore, por mais bem-regada que seja, crescerá tanto, que os seus galhos cheguem até as nuvens. Todas elas estão condenadas a morrer como seres humanos mortais e a se juntarem com aqueles que descem para o mundo dos mortos .
15 “ ‘Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Ní ọjọ́ ti a mú u wá sí isà òkú mo fi ọ̀fọ̀ ṣíṣe bo orísun omi jíjìn náà, mo dá àwọn ìṣàn omi rẹ̀ dúró, àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi rẹ̀ ní a dí lọ́nà. Nítorí rẹ̀ mo fi ìwúwo ọkàn wọ Lebanoni ní aṣọ, gbogbo igi igbó gbẹ dànù.
15 O Senhor Deus diz o seguinte: — No dia em que a árvore descer ao mundo dos mortos, farei com que as águas que estão debaixo da terra a cubram, como sinal de tristeza. Farei com que os rios parem e não deixarei que os muitos ribeirões corram. A árvore morreu, e por isso trarei escuridão sobre os montes Líbanos e farei com que sequem todas as árvores da floresta.
16 Mo mú kí orílẹ̀-èdè wárìrì sì ìró ìṣubú rẹ̀ nígbà tí mo mú un wá sí ìsàlẹ̀ isà òkú pẹ̀lú àwọn tí ó lọ sí ọ̀gbun ìsàlẹ̀. Nígbà náà gbogbo igi Edeni, àṣàyàn àti èyí tí ó dára jùlọ nínú Lebanoni, gbogbo igi tí ó ní omi dáradára ni a tù nínú ni ayé ìsàlẹ̀.
16 Quando eu a lançar no mundo dos mortos, o barulho da sua queda abalará as nações. Todas as árvores do Éden e todas as árvores do Líbano, as mais belas e mais bem-regadas e que já estão no mundo lá de baixo, vão ficar contentes com a sua queda.
17 Àwọn tí ó ń gbé ní abẹ́ òjìji rẹ̀, àwọn àjèjì rẹ ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè náà, ti lọ sí ìsàlẹ̀ isà òkú pẹ̀lú rẹ̀, ní dídárapọ̀ mọ́ àwọn tí a fi idà pa.
17 Elas irão com ela ao mundo dos mortos para se juntar com aquelas que já haviam caído. E todos os que viviam na sua sombra serão espalhados entre as nações.
18 “ ‘Èwo lára igi Edeni ní a lè fiwé ọ ní dídán àti ọláńlá? Síbẹ̀ ìwọ, gan an wá sílẹ̀ pẹ̀lú àwọn igi Edeni lọ sí ìsàlẹ̀ ilẹ̀; ìwọ yóò sùn ni àárín àwọn aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa.
18 — A árvore é o rei do Egito e todo o seu povo. Nem mesmo as árvores do Éden eram tão altas e vistosas. Mas agora, como as árvores do Éden, ela descerá ao mundo dos mortos e se juntará aos que não foram circuncidados e aos que forem mortos na guerra. Eu, o Senhor Deus, falei.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Ezequiel 31, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.