Ezequiel 24

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Ní ọdún kẹsànán, oṣù kẹwàá, ọjọ́ kẹwàá, ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
1 Novamente, no ano nono, no décimo mês, no décimo dia do mês, a palavra do SENHOR veio a mim, dizendo:
2 “Ọmọ ènìyàn, kọ ọjọ́ náà sílẹ̀, ọjọ́ náà gan an, nítorí ọba Babeli náà ti da ojú ti Jerusalẹmu ní ọjọ́ yìí gan an.
2 Filho do homem, escreve tu o nome deste dia, deste mesmo dia; o rei de Babilônia se pôs contra Jerusalém neste mesmo dia.
3 Sì pa òwe yìí fún ilé ọlọ́tẹ̀ náà, sọ fún wọn pé: ‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí:
3 E profere uma parábola à casa rebelde, e dize-lhes: Assim diz o Senhor DEUS: Põe a panela, põe-na, e derrama água dentro dela.
4 Kó àwọn ègé ẹran tí a gé náà sínú rẹ̀,
4 Ajunta os seus pedaços dentro dela, cada bom pedaço, a coxa e a espádua; enche-a com os ossos escolhidos.
5 mú àwọn tí ó jọjú nínú agbo ẹran.
5 Escolhe dentre o rebanho, e queima também os ossos debaixo dela, e faze-a ferver bem, e deixa ferver os seus ossos dentro dela.
6 Nítorí báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí:
6 Portanto, assim diz o Senhor DEUS: Ai da cidade sanguinária, da panela cuja escória está dentro, e cuja escória não saiu dela! Traze-a para fora pedaço por pedaço; não caia sorte sobre ela.
7 “ ‘Nítorí ẹ̀jẹ̀ tí ó ta sílẹ̀ wà ní àárín rẹ̀;
7 Porque o seu sangue está no meio dela; ela o pôs sobre o topo de uma rocha; não o derramou sobre a terra, para o cobrir com pó.
8 Láti bá à le jẹ́ kí ìbínú kí ó dé láti gbẹ̀san
8 Para que isso pudesse fazer subir a fúria, para tomar vingança, eu pus o seu sangue sobre o topo de uma rocha, para que isto não fosse coberto.
9 Nítorí náà báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí:
9 Portanto, assim diz o Senhor DEUS: Ai da cidade sanguinária! Eu mesmo farei uma pilha para um grande fogo.
10 Nítorí náà kó igi náà jọ sí i,
10 Amontoa madeira, acende o fogo, consome a carne, e tempera-a bem, e deixa os ossos queimarem.
11 Lẹ́yìn náà gbé òfìfo ìkòkò náà lórí ẹyin iná
11 Então, põe-na vazia sobre os seus carvões, para que o seu bronze possa estar quente, e possa queimar, e para que sua imundícia possa se fundir nela, e para que sua escória possa ser consumida.
12 Ó ti ba gbogbo akitiyan jẹ:
12 Ela se cansou com mentiras; e sua grande escória não saiu dela; sua escória estará no fogo.
13 “ ‘Nísinsin yìí èérí rẹ̀ ni ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wà. Nítorí mo gbìyànjú láti wẹ̀ ọ́ mọ́, ṣùgbọ́n ìwọ kò sì mọ́ kúrò nínú ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ rẹ, a kì yóò sì tún wẹ̀ ọ mọ́ kúrò nínú èérí rẹ, títí èmi yóò fi jẹ́ kí ìbínú mi balẹ̀ sórí rẹ̀.
13 Na tua imundícia está a lascívia, porquanto te purguei, e tu não foste purgada, não serás mais purgada da tua imundícia, até que eu tenha feito minha fúria descansar sobre ti.
14 “ ‘Èmi Olúwa ni ó sọ ọ́, yóò sì ṣe, èmi yóò sì ṣe é. Èmi kì yóò padà sẹ́yìn; bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò dá sí i, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò yí ọkàn mi padà; gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ, àti gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ, ni wọn yóò dá ọ lẹ́jọ́, ni Olúwa Olódùmarè wí.’ ”
14 Eu, o SENHOR, o disse: Isso passará, e eu o farei; não voltarei atrás, nem pouparei, nem me arrependerei; de acordo com os teus caminhos, e de acordo com os teus feitos, eles te julgarão, diz o Senhor DEUS.
15 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá pé:
15 Também, a palavra do SENHOR veio a mim, dizendo:
16 “Ọmọ ènìyàn, kíyèsi i, mo mú ìfẹ́ ojú rẹ kúrò ní ọ̀dọ̀ rẹ, nípa lílù kan. Ṣùgbọ́n ìwọ kò gbọdọ̀ gbààwẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ sọkún, bẹ́ẹ̀ ni omijé ojú rẹ kò gbọdọ̀ kán sílẹ̀.
16 Filho do homem, eis que, eu tomo de ti o desejo dos teus olhos com um golpe; mesmo assim, não lamentarás, nem chorarás, nem tuas lágrimas escorrerão.
17 Má ṣe sọkún, má ṣe gbààwẹ̀ fún òkú. Wé ọ̀já sí orí rẹ, sì bọ bàtà sí ẹsẹ̀ rẹ, má ṣe bo ètè ìsàlẹ̀ rẹ, ma ṣe jẹ oúnjẹ tí àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ń jẹ gẹ́gẹ́ bí àṣà.”
17 Deixa de chorar, não faças luto pelos mortos; prende o adorno da tua cabeça sobre ti, e põe tuas sandálias nos teus pés, e não cubras os teus lábios, e não comas o pão dos homens.
18 Báyìí ni mo sọ̀rọ̀ fún àwọn ènìyàn ní òwúrọ̀, ní àṣálẹ́ ìyàwó mi sì kú. Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, mo ṣe bí a ti pàṣẹ fún mi.
18 Assim, eu falei ao povo pela manhã, e à tarde morreu minha mulher; e eu fiz pela manhã como me foi mandado.
19 Lẹ́yìn náà àwọn ènìyàn bi mí léèrè pé, “Ṣe o kò ni sọ fún wa ohun ti nǹkan wọ̀nyí ní láti ṣe pẹ̀lú wa?”
19 E o povo me disse: Tu não nos dirás o que estas coisas são para nós, para que tu faças assim?
20 Mo sọ báyìí fún wọn pé, “Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
20 Então eu lhes respondi: A palavra do SENHOR veio a mim, dizendo:
21 Sọ fún ilé Israẹli, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi i, èmi yóò sọ ibi mímọ́ mi di ibi àìmọ́ tayọ agbára yín, ìfẹ́ ojú yín, ìkáàánú yín, àti ọmọ yín ọkùnrin àti àwọn ọmọ yín obìnrin tí ẹ̀yin fi sílẹ̀ sẹ́yìn yóò ṣubú nípa idà.
21 Fala à casa de Israel: Assim diz o Senhor DEUS: Eis que eu profanarei o meu santuário, a excelência da vossa força, o desejo dos vossos olhos, e aquilo de que sua alma se compadece; e vossos filhos e vossas filhas, a quem deixastes, cairão à espada.
22 Ẹyin yóò sì ṣe bí mo ti ṣe. Ẹ̀yin kì yóò bo ìsàlẹ̀ ojú yín tàbí jẹ oúnjẹ ti àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ń jẹ gẹ́gẹ́ bí àṣà.
22 E vós fareis como eu fiz; não cobrireis vossos lábios, nem comereis o pão dos homens.
23 Ẹ̀yin yóò fi àwọn ọ̀já wé àwọn orí yín àti àwọn bàtà ni ẹsẹ̀ yín, ẹ̀yin kì yóò ṣọ̀fọ̀ tàbí sọkún, ṣùgbọ́n ẹ̀yin yóò ṣòfò dànù nítorí àwọn àìṣedéédéé yín, ẹ̀yin yóò sì máa kérora láàrín ara yín.
23 E vossos adornos estarão sobre vossas cabeças, e vossas sandálias nos vossos pés; não lamentareis, nem chorareis, mas definhareis por vossas iniquidades, e lamentareis uns com os outros.
24 Esekiẹli yóò jẹ àmì fún un yín; ẹ̀yin yóò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí òun ti ṣe. Nígbà tí èyí bá ṣẹlẹ̀, ẹ̀yin yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa Olódùmarè.’
24 Assim, Ezequiel é sobre vós um sinal; de acordo com tudo o que ele fez, vós fareis; e quando isso vier, sabereis que eu sou o Senhor DEUS.
25 “Pẹ̀lúpẹ̀lú ìwọ, Ọmọ ènìyàn, kì yóò ha jẹ́ pé, ní ọjọ́ náà, nígbà ti mo bá gba agbára wọn, ayọ̀ wọn àti ògo wọn, ìfẹ́ ojú wọn, ohun tí wọn gbé ọkàn wọn lé, àti àwọn ọmọ ọkùnrin wọn pẹ̀lú àwọn ọmọ obìnrin wọn kúrò lọ́dọ̀ wọn,
25 Também tu, filho do homem, no dia em que eu lhes tomar a sua força, a alegria da sua glória, o desejo dos seus olhos, e aquilo sobre o que eles puserem suas mentes, seus filhos e suas filhas,
26 ní ọjọ́ náà ẹni tí ó bá sálà yóò tọ̀ ọ́ wá láti sọ ìròyìn náà fún ọ.
26 para que aquele que escapar naquele dia, venha a ti para fazer com que tu o ouças com teus ouvidos?
27 Ní ọjọ́ náà ẹnu rẹ yóò sì ṣí; ìwọ yóò sọ̀rọ̀, ìwọ kì yóò sì yadi mọ́. Báyìí ìwọ yóò jẹ́ àmì fún wọn; wọn yóò sì mọ̀ pé èmi ní Olúwa.”
27 Naquele dia tua boca se abrirá àquele que tiver escapado, e tu falarás, e não serás mais mudo; e tu serás um sinal para eles, e saberão que eu sou o SENHOR.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Ezequiel 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.