Ezequiel 18

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé:
1 A palavra do SENHOR veio a mim novamente, dizendo:
2 “Kín ni ẹ̀yin rò tí ẹ̀yin fi ń pa òwe nípa Israẹli wí pé:
2 Que quereis vós dizer, usando este provérbio que diz respeito à terra de Israel, dizendo: Os pais comeram uvas azedas, e os dentes dos filhos é que se embotaram?
3 “Bí mo ti wà láààyè ni Olúwa Olódùmarè wí, ẹ̀yin kí yóò pa òwe yìí mọ́ ni Israẹli.
3 Como eu vivo, diz o Senhor DEUS, não tereis mais ocasião para usarem este provérbio em Israel.
4 Nítorí pé èmi ló ní gbogbo ọkàn, ọkàn baba tèmi bẹ́ẹ̀ ni ọkàn ọmọ pàápàá jẹ tèmi, ọkàn tó bá ṣẹ̀ ní yóò kú.
4 Eis que todas as almas são minhas; como a alma do pai, assim também a alma do filho é minha; a alma que pecar, essa morrerá.
5 “Bí ọkùnrin olódodo kan bá wà,
5 Mas se um homem for justo, e fizer aquilo que é lícito e certo,
6 tí kò bá wọn jẹun lórí òkè gíga,
6 que não come sobre os montes, nem levanta seus olhos para os ídolos da casa de Israel, nem contamina a mulher do seu vizinho, nem chega a uma mulher menstruada,
7 Kò sì ni ẹnikẹ́ni lára,
7 e não oprime a ninguém, mas restaura ao devedor o seu penhor; não prejudica a ninguém através de violência; dando o seu pão ao faminto e cobrindo ao nu com roupa;
8 Ẹni tí kò fi fún ni láti gba ẹ̀dá,
8 ele não dá sobre usura, nem toma nenhum aumento; que retira sua mão da iniquidade; executando verdadeiro juízo entre homem e homem;
9 Tí ó ń tẹ̀lé àṣẹ mi,
9 andando nos meus estatutos, e guardado os meus juízos, para lidar verdadeiramente; ele é justo, certamente viverá, diz o Senhor DEUS.
10 “Bí ó bá bi ọmọkùnrin, oníwà ipá, tó ń jalè, tó tún ń pànìyàn, tó sì ń ṣe gbogbo àwọn nǹkan wọ̀nyí sí arákùnrin rẹ̀
10 Se ele gerar um filho que for ladrão, derramador de sangue, que fizer ao semelhante qualquer uma destas coisas;
11 (tí kò sì ṣe ọ̀kan nínú gbogbo iṣẹ́ wọ̀n-ọn-nì):
11 e que não fizer nenhum daqueles deveres, mas que coma sobre os montes, e contamine a mulher do seu vizinho;
12 Ó ni àwọn tálákà àti aláìní lára,
12 oprimindo o pobre e necessitado; prejudicando através de violência; não restaurando o penhor, e levantando seus olhos aos ídolos; cometendo abominação;
13 Ó ń fi owó ya ni pẹ̀lú èlé, ó sì tún ń gba èlé tó pọ̀jù.
13 dando sobre usura, e tomando aumento; ele viverá? Ele não viverá. Aquele que tem feito todas estas abominações, certamente morrerá; seu sangue será sobre ele.
14 “Bí ọkùnrin yìí bá bímọ ọkùnrin, tó sì rí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ ti baba rẹ ń ṣẹ̀ yìí, tó sì bẹ̀rù, ti kò ṣe irú rẹ̀:
14 Agora, eis que se ele gerar um filho que, vendo todos os pecados cometido por seu pai, e considerar, e não fizer como tal;
15 “Tí kò jẹun lójúbọ lórí òkè gíga
15 que não come sobre os montes, nem levanta os seus olhos para os ídolos da casa de Israel, e não contamina a mulher de seu vizinho,
16 tí kò sì ni ẹnikẹ́ni lára,
16 nem oprime a ninguém, e não retém o penhor, nem prejudica através de violência, mas dá seu pão ao faminto, e cobre o nu com roupa,
17 Ó ń yọ ọwọ́ rẹ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀,
17 que tiver retirado a sua mão do pobre, que não recebe usura nem aumento; executando meus juízos; andando em meus estatutos; ele não morrerá pela iniquidade de seu pai, ele certamente viverá.
18 Ṣùgbọ́n baba rẹ̀ ni yóò kú fún ẹ̀ṣẹ̀ ara rẹ̀, nítorí pé ó jẹ́ arẹ́nijẹ, ó jalè arákùnrin rẹ, ó ṣe ohun tí kò dára láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.
18 Quanto ao seu pai, porque ele cruelmente oprimiu, prejudicou o seu irmão pela violência, e fez aquilo que não é bom entre seu povo, eis que ele morrerá em sua iniquidade.
19 “Síbẹ̀, ẹ tún ń béèrè pé, ‘Kí ló dé ti ọmọ kò fi ní í ru ẹ̀bi baba rẹ̀?’ Níwọ́n ìgbà tí ọmọ ti ṣe ohun tó tọ́, tó sì yẹ, tó sì ti kíyèsi ara láti pa gbogbo àṣẹ mi mọ́, nítòótọ́ ni pé yóò yè.
19 Ainda assim dizeis: Por que o filho não carrega a iniquidade do pai? Quando o filho tiver feito aquilo que é lícito e certo, e tiver guardado todos os meus estatutos, e os tiver feito, ele certamente viverá.
20 Ọkàn tí ó bá ṣẹ̀ ní yóò kú. Ọmọ kò ní í ru ẹ̀bi baba rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni baba náà kò ní ru ẹ̀bi ọmọ rẹ̀. Ìwà rere ènìyàn rere yóò wà lórí rẹ̀, ìwà búburú ti ènìyàn búburú náà la ó kà sí i lọ́rùn.
20 A alma que pecar, essa morrerá; o filho não carregará a iniquidade do pai, nem o pai carregará a iniquidade do filho. A justiça do justo ficará sobre ele, e a perversidade do perverso ficará sobre ele.
21 “Ṣùgbọ́n bí ènìyàn búburú bá yípadà kúrò nínú gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ tó ti dá, tó sì bẹ̀rẹ̀ sí í pa àṣẹ mi mọ́, tó sì ń ṣe ohun tó tọ́ àti ohun tó yẹ, nítòótọ́ ni yóò yè, kò sì ní kú.
21 Contudo, se o perverso se desviar de todos os seus pecados que cometeu, e guardar todos os meus estatutos, e fizer aquilo que é lícito e certo, certamente viverá; ele não morrerá.
22 A kò sì ní rántí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ tó ti dá tẹ́lẹ̀ láti kà á sí lọ́rùn nítorí tí ìwà òdodo rẹ tó fihàn, yóò yè.
22 Todas as suas transgressões que cometeu não serão mencionadas a ele; na sua justiça que fez, ele viverá.
23 Ǹjẹ́ èmi ha ni inú dídùn si ikú ènìyàn búburú bí í? Ní Olúwa Olódùmarè wí pé, dípò èyí inú mi kò ha ni i dùn nígbà tó ba yípadà kúrò ni àwọn ọ̀nà búburú rẹ̀ kí ó sì yè?
23 Tenho eu qualquer prazer em que todo o perverso morra? Diz o Senhor DEUS; e não que ele se desvie de seus caminhos, e viva?
24 “Ṣùgbọ́n bí ènìyàn rere bá yípadà kúrò ni ọ̀nà òdodo rẹ̀ tó sì ń dẹ́ṣẹ̀, tí ó sì tún ń ṣe àwọn ohun ìríra tí ènìyàn búburú ń ṣe, yóò wa yè bí? A kì yóò rántí ọ̀kankan nínú ìwà rere rẹ̀ mọ́, nítorí ó ti jẹ̀bi ìwà àrékérekè àti ẹ̀ṣẹ̀ tó dá, yóò sì kú.
24 Mas, quando o justo se afasta da sua justiça e comete a iniquidade, e faz de acordo com as abominações que o homem perverso faz, ele viverá? Todas as suas justiças que ele fez não serão mencionadas; em sua transgressão que ele transgrediu, e em seu pecado que ele pecou, neles ele morrerá.
25 “Bẹ́ẹ̀ ni, ẹ̀yin tún wí pé, ‘Ọ̀nà Olúwa kò gún.’ Gbọ́ nísinsin yìí, ìwọ ilé Israẹli. Ọ̀nà mi ni kò ha gún? Kì í wa ṣé pé ọ̀nà tiyín gan an ni kò gún?
25 Ainda assim, dizeis: O caminho do Senhor não é reto. Ouvi agora, ó casa de Israel: Meu caminho não é reto? Não são seus caminhos inconstantes?
26 Bí olódodo ba yípadà kúrò nínú olódodo rẹ̀, tó sì dẹ́ṣẹ̀, yóò ku fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, yóò kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tó ti dá.
26 Quando um homem justo se afasta da sua justiça e comete a iniquidade, e morre nela, por causa da sua iniquidade que fez, ele morrerá.
27 Ṣùgbọ́n bi ènìyàn búburú bá yípadà kúrò nínú ìwà búburú tó ti ṣe, tó sì ṣe ohun tó tọ́ àti ohun tó yẹ, yóò gba ẹ̀mí rẹ̀ là.
27 Novamente, quando o homem perverso se desvia da sua perversidade que cometeu, e faz aquilo que é lícito e certo, salvará sua alma viva.
28 Nítorí pé ó ronú lórí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tó ti dá, ó sì yípadà kúrò nínú wọn, nítòótọ́ ni yóò yè; kì yóò sí kú.
28 Porque ele considera, e se afasta de todas as suas transgressões que cometeu; certamente viverá, não morrerá.
29 Síbẹ̀, ilé Israẹli wí pé, ‘Ọ̀nà Olúwa kò gún.’ Ọ̀nà mi kò ha tọ́ bí ilé Israẹli? Kì í wa ṣe pè ọ̀nà tiyín gan an ni ko gún?
29 Ainda assim, diz a casa de Israel: O caminho do Senhor não é reto. Ó casa de Israel, não são retos os meus caminhos? Não são desiguais os vossos caminhos?
30 “Nítorí náà, ilé Israẹli, èmi yóò da yín lẹ́jọ́, gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà ẹnìkọ̀ọ̀kan yín bá ṣe rí ni Olúwa Olódùmarè wí. Ẹ yípadà! Kí ẹ si yí kúrò nínú gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ yín, bẹ́ẹ̀ ni ìrékọjá kì yóò jẹ́ ọ̀nà ìṣubú yín.
30 Portanto, eu vos julgarei, ó casa de Israel, cada um de acordo com os seus caminhos, diz o Senhor DEUS. Arrependei-vos e desviai-vos de todas as vossas transgressões, assim a iniquidade não será a vossa ruína.
31 Ẹ kọ̀ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ ti ẹ ti dá sílẹ̀, kí ẹ sì gba ọkàn àti ẹ̀mí tuntun. Nítorí kí ló fi máa kú, ilé Israẹli?
31 Lançai de vós todas as vossas transgressões com as quais transgredistes, e fazei-vos um coração novo e um espírito novo; pois, por que morrereis, ó casa de Israel?
32 Nítorí pé inú mi kò dùn sí ikú ẹnikẹ́ni ni Olúwa Olódùmarè wí. Nítorí náà, ẹ yípadà kí ẹ sì yè!
32 Pois eu não tenho prazer na morte daquele que morre, diz o Senhor DEUS; portanto, convertei-vos, e vivei.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Ezequiel 18, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.