Êxodo 6

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH

Sair da comparação
NTLH Nova Tradução na Linguagem de Hoje 2000
1 Nígbà náà ní Olúwa sọ fún Mose pé, “Ní ìsin yìí, ìwọ yóò rí ohun tí èmi yóò ṣe sí Farao pẹ̀lú ọwọ́ agbára ńlá mi ni yóò fi jẹ́ kí wọn lọ; pẹ̀lú ọwọ́ agbára ńlá mi, òun yóò lé wọn jáde kúrò ní orílẹ̀-èdè rẹ̀.”
1 Então o Senhor Deus respondeu a Moisés: — Agora você verá o que vou fazer com o rei do Egito. Eu vou obrigá-lo a deixar que o meu povo vá embora. Sim, eu o forçarei a expulsar os israelitas do seu país.
2 Ọlọ́run sì tún sọ fún Mose pé, “Èmi ni Olúwa.
2 Deus disse a Moisés: — Eu sou o
3 Mo fi ara hàn Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu bí Ọlọ́run alágbára, ṣùgbọ́n nípa orúkọ mi Olúwa, Èmi kò fi ara mi hàn wọ́n.
3 Eu apareci a Abraão, a Isaque e a Jacó como o Deus Todo-Poderoso, porém não deixei que me conhecessem pelo meu nome de .
4 Èmí sì tún fi ìdí májẹ̀mú mi múlẹ̀ pẹ̀lú wọn láti fún wọn ní ilẹ̀ Kenaani, ilẹ̀ tí wọn gbé gẹ́gẹ́ bí àjèjì.
4 Fiz uma aliança com eles e prometi dar-lhes a terra de Canaã, onde tinham vivido como estrangeiros.
5 Èmi sì ti tún gbọ́ kíkùn àwọn ọmọ Israẹli àwọn tí àwọn ará Ejibiti mú gẹ́gẹ́ bí ẹrú, àti pé èmi sì ti rántí májẹ̀mú mi.
5 Agora eu ouvi os gemidos dos israelitas, que estão sendo escravizados pelos egípcios, e lembrei da aliança que fiz com eles.
6 “Sọ fún àwọn ará ilé Israẹli, ‘Èmi ni Olúwa, Èmi yóò sọ yín di òmìnira kúrò nínú àjàgà àwọn ará Ejibiti. Èmi yóò sì gbà yín sílẹ̀ kúrò ní oko ẹrú wọn. Èmi yóò dá a yín sílẹ̀ pẹ̀lú apá nínà (àwọn iṣẹ́ ìyanu) àti pẹ̀lú ìdájọ́ ńlá.
6 Portanto, diga aos israelitas o seguinte: “Eu sou o Senhor . Vou livrá-los da escravidão do Egito. Estenderei o braço poderoso para fazer cair sobre os egípcios um castigo horrível e salvarei vocês.
7 Èmi yóò mú un yín bí ènìyàn mi, èmi yóò sì jẹ́ Ọlọ́run yín. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, ẹni tí ó mú un yín jáde kúrò nínú àjàgà àwọn ará Ejibiti.
7 Farei com que vocês sejam o meu povo e eu serei o seu Deus. Vocês ficarão sabendo que eu sou o Senhor , seu Deus, o Deus que os vai livrar da escravidão no Egito.
8 Èmi yóò mú un yín wá ilẹ̀ náà ti èmi ti búra pẹ̀lú ìgbọ́wọ́sókè láti fi fún Abrahamu. Isaaki àti Jakọbu. Èmi yóò fi fún un yín bí ohun ìní, Èmi ni Olúwa.’ ”
8 Eu os levarei para a terra que jurei que daria a Abraão, a Isaque e a Jacó. E eu darei essa terra para ser propriedade de vocês. Eu sou o Senhor .”
9 Mose sì sọ èyí fún àwọn ará Israẹli, ṣùgbọ́n wọn kò fi etí sílẹ̀ sí Mose nítorí ọkàn wọn tó rẹ̀wẹ̀sì àti nítorí ìgbèkùn búburú bí ohun tí ó ti kọ́ sọ kó wọn sí ní oko ẹrú wọn.
9 Moisés repetiu essas palavras aos israelitas, mas eles não quiseram ouvi-lo, pois estavam desanimados por causa da dureza da sua escravidão.
10 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose.
10 Então o Senhor disse a Moisés:
11 “Lọ, sọ fún Farao ọba Ejibiti pé kí ó jẹ́ kí àwọn ará Israẹli lọ kúrò ní orílẹ̀-èdè rẹ̀.”
11 — Vá dizer a Faraó, rei do Egito, que deixe que os israelitas saiam do país.
12 Ṣùgbọ́n Mose sọ fún Olúwa pé, “Nígbà ti àwọn ará Israẹli tó jẹ́ ènìyàn mi kó fetí sí ọ̀rọ̀ mi, báwo ni Farao yóò ṣe fetí sí ọ̀rọ̀ mi, nígbà ti mo jẹ́ akólòlò?”
12 Porém Moisés respondeu ao Senhor : — Se até os israelitas não querem me dar atenção, o rei também não vai querer. Eu não tenho facilidade para falar.
13 Olúwa bá ìran Mose àti Aaroni sọ̀rọ̀ nípa àwọn ará Israẹli àti Farao ọba Ejibiti, ó pàṣẹ fún wọn pé kí wọn kó àwọn Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti.
13 No entanto o Senhor ordenou que Moisés e Arão dissessem aos israelitas e a Faraó, rei do Egito, que eles dois tinham ordem para tirar do país o povo de Israel.
14 Wọ̀nyí ni olórí ìran wọn:
14 Esta é a lista dos grupos de famílias dos antepassados de Moisés e Arão: Rúben, o primeiro filho de Jacó, foi pai de quatro filhos: Enoque, Palu, Hezrom e Carmi. São esses os grupos de famílias de Rúben.
15 Àwọn ọmọ Simeoni ni:
15 Simeão foi pai de seis filhos: Jemuel, Jamim, Oade, Jaquim, Zoar e Saul, filho de uma mulher cananeia. São esses os grupos de famílias de Simeão.
16 Ìwọ̀nyí ni orúkọ àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn:
16 Levi foi pai de três filhos: Gérson, Coate e Merari. Levi viveu cento e trinta e sete anos.
17 Àwọn ọmọ Gerṣoni ni ìran wọn ni:
17 Gérson foi pai de dois filhos: Libni e Simei, e eles tiveram muitos descendentes.
18 Àwọn ọmọ Kohati ni:
18 São estes os filhos de Coate: Anrão, Isar, Hebrom e Uziel. Coate viveu cento e trinta e três anos.
19 Àwọn ọmọ Merari ni:
19 Merari foi pai de dois filhos: Mali e Musi. São esses os grupos de famílias de Levi, com os seus descendentes.
20 Amramu sì fẹ́ Jokebedi arábìnrin baba rẹ̀ ní ìyàwó. Jokebedi sì bí Aaroni àti Mose fún un.
20 Anrão casou com Joquebede, sua tia por parte de pai, e ela lhe deu dois filhos: Arão e Moisés. Anrão viveu cento e trinta e sete anos.
21 Àwọn ọmọ Isari ni:
21 Isar foi pai de três filhos: Corá, Nefegue e Zicri.
22 Àwọn ọmọ Usieli ni:
22 Uziel também foi pai de três filhos: Misael, Elzafã e Sitri.
23 Aaroni fẹ́ Eliṣeba ọmọbìnrin Amminadabu tí í ṣe arábìnrin Nahiṣoni, ó sì bí Nadabu, Abihu, Eleasari àti Itamari.
23 Arão casou com Eliseba, filha de Aminadabe e irmã de Nasom. Ela lhe deu quatro filhos: Nadabe, Abiú, Eleazar e Itamar.
24 Àwọn ọmọ Kora ni:
24 Corá foi pai de três filhos: Assir, Elcana e Abiasafe. São esses os grupos de famílias de Corá.
25 Eleasari ọmọ Aaroni fẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọbìnrin Putieli ní ìyàwó, ó sì bí Finehasi fún un.
25 Eleazar, filho de Arão, casou com uma das filhas de Putiel, e ela lhe deu um filho, chamado Fineias. São esses os chefes das famílias e dos grupos de famílias da tribo de Levi.
26 Aaroni àti Mose yìí kan náà ni Olúwa sọ fún pé, “Ẹ kó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti ní ìsọ̀rí ìsọ̀rí.”
26 Arão e Moisés foram os que receberam do Senhor Deus esta ordem: “Tirem do Egito as tribos de Israel.”
27 Àwọn ni ó bá Farao ọba Ejibiti sọ̀rọ̀ nípa kíkó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni Ejibiti, àní Mose àti Aaroni yìí kan náà ni.
27 Foram eles que falaram com Faraó, rei do Egito, a fim de tirar de lá os israelitas.
28 Nígbà tí Olúwa bá Mose sọ̀rọ̀ ni Ejibiti,
28 Quando o Senhor falou com Moisés, no Egito,
29 Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Èmi ni Olúwa. Sọ ohun gbogbo ti mo ti sọ fún ọ fún Farao ọba Ejibiti.”
29 ele disse: — Eu sou o
30 Ṣùgbọ́n Mose sì wí ní iwájú Olúwa pé, “Níwọ́n ìgbà ti mo jẹ́ akólòlò, ọ̀nà dà ti Farao yóò ṣe fi etí sí mi?”
30 Porém Moisés respondeu: — Ó

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Êxodo 6, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.