Êxodo 35

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Mose pe gbogbo ìjọ Israẹli ó sì wí fún wọn pé, “Wọ̀nyí ni àwọn ohun ti Olúwa ti pàṣẹ fún un yín láti ṣe.
1 E Moisés reuniu toda a congregação dos filhos de Israel e lhes disse: Estas são as palavras que o SENHOR ordenou, para que se cumprissem.
2 Fún ọjọ́ mẹ́fà ni kí ẹ fi ṣiṣẹ́, ṣùgbọ́n ọjọ́ keje yóò jẹ́ ọjọ́ mímọ́ fún yín, ọjọ́ ìsinmi ni sí Olúwa. Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe iṣẹ́ kankan ni ọjọ́ náà ní a ó pa.
2 Seis dias se trabalhará, mas o sétimo dia será para vós dia santo, o shabat de descanso para o SENHOR. Todo aquele que nele fizer trabalho morrerá.
3 Ẹ má ṣe dáná kankan ní ibùgbé yín ní ọjọ́ ìsinmi.”
3 Não acendereis fogo em nenhuma das vossas habitações no dia do shabat.
4 Mose sọ fún gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa pàṣẹ.
4 E Moisés falou a toda a congregação dos filhos de Israel, dizendo: Isto é o que o SENHOR ordenou, dizendo:
5 Láti inú ohun tí ẹ ni ni kí ẹ ti mú ọrẹ fún Olúwa. Ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ ni kí ó mú ọrẹ fún Olúwa ní ti:
5 Tomai dentre vós uma oferta ao SENHOR. Todo aquele que tiver um coração disposto, que a traga, uma oferta ao SENHOR: ouro, e prata, e bronze,
6 aṣọ aláró, elése àlùkò, òdòdó àti ọ̀gbọ̀ dáradára;
6 e azul, e púrpura, e escarlate, e linho fino, e pelo de cabra,
7 awọ àgbò tí a kùn ní pupa àti awọ màlúù;
7 e peles de carneiro tingidas de vermelho, e peles de texugo, e madeira de acácia,
8 òróró olifi fún títan iná;
8 e óleo para a luz, e especiarias para o óleo da unção, e para o incenso aromático,
9 òkúta óníkìsì àti òkúta tí a tò sí ẹ̀wù efodu àti ìgbàyà.
9 e pedras de ônix, e pedras de engaste para o éfode, e para o peitoral.
10 “Gbogbo ẹni tí ó ní ọgbọ́n láàrín yín, kí ó wa, kí ó sì wá ṣe gbogbo ohun tí Olúwa ti pàṣẹ:
10 E todos os sábios de coração entre vós virão e farão tudo que o SENHOR ordenou;
11 “àgọ́ náà pẹ̀lú àgọ́ rẹ àti ìbòrí rẹ̀, kọ́kọ́rọ́ rẹ̀, pákó rẹ̀, ọ̀pá rẹ̀, ọ̀wọ́n rẹ̀ àti ihò ìtẹ̀bọ̀ rẹ̀;
11 o tabernáculo, sua tenda, e sua coberta, os seus colchetes, e suas tábuas, suas barras, suas colunas, e suas bases;
12 Àpótí náà pẹ̀lú ọ̀pá rẹ̀, ìbò àánú àti aṣọ títa náà tí ó síji bò ó.
12 a arca, e as suas varas, com o propiciatório e o véu de cobertura;
13 Tábìlì náà pẹ̀lú òpó rẹ̀ àti gbogbo ohun èlò rẹ̀ àti àkàrà ìfihàn náà.
13 a mesa, e as suas varas, e todos os seus utensílios, e o pão da proposição;
14 Ọ̀pá fìtílà tí ó wà fún títanná pẹ̀lú ohun èlò rẹ̀, fìtílà àti òróró fún títanná.
14 o candelabro para a luz, e os seus utensílios, e suas lâmpadas, com o óleo para a luz;
15 Pẹpẹ tùràrí náà pẹ̀lú ẹsẹ̀ rẹ̀, òróró ìtasórí àti tùràrí dídùn;
15 e o altar do incenso, e suas varas, e o óleo da unção, e o incenso aromático, e a cortina da porta à entrada do tabernáculo;
16 Pẹpẹ ẹbọ sísun pẹ̀lú ojú ààrò idẹ rẹ̀, òpó rẹ̀ àti gbogbo ohun èlò rẹ̀;
16 o altar da oferta queimada, com sua grade de bronze, suas varas, e todos os seus utensílios, a pia e sua base;
17 Aṣọ títa ti àgbàlá pẹ̀lú, ọ̀wọ́n àti ihò ìtẹ̀bọ̀ rẹ̀ àti aṣọ títa fún ẹnu-ọ̀nà àgbàlá náà.
17 as cortinas do pátio, suas colunas, e suas bases, e a cortina da porta do pátio;
18 Èèkàn àgọ́ náà fún àgọ́ náà àti fún àgbàlá àti okùn wọn.
18 as estacas do tabernáculo, e as estacas do pátio, e suas cordas;
19 Aṣọ híhun láti ṣiṣẹ́ ní ibi mímọ́ aṣọ mímọ́ fún Aaroni àlùfáà àti aṣọ fún àwọn ọmọ rẹ̀ nígbà tí wọ́n sìn bí àlùfáà.”
19 as vestes do serviço, para realizar o serviço no lugar santo, as vestes santas para Arão, o sacerdote, e as vestes dos seus filhos, para ministrar no ofício sacerdotal.
20 Gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli sì kúrò níwájú Mose,
20 E toda a congregação dos filhos de Israel saiu da presença de Moisés.
21 olúkúlùkù ẹni tí ó fẹ́ àti ẹni tí ọkàn rẹ̀ gbé sókè wá, wọ́n sì mú ọrẹ fún Olúwa, fún iṣẹ́ àgọ́ àjọ, fún gbogbo ìsìn rẹ̀ àti fún aṣọ mímọ́ náà.
21 E veio, todo aquele cujo coração o moveu, e todo aquele cujo espírito o tornou disposto, e trouxeram a oferta ao SENHOR para a obra do tabernáculo da congregação, e para todo o seu serviço, e para as vestes santas.
22 Gbogbo àwọn tí ó fẹ́, ọkùnrin àti obìnrin, wọ́n wá wọ́n sì mú onírúurú ìlẹ̀kẹ̀ wúrà: òrùka etí, òrùka àti ọ̀ṣọ́. Gbogbo wọn mú wúrà gẹ́gẹ́ bí ọrẹ wá fún Olúwa.
22 E vieram, tanto homens quanto mulheres, com muitos que estavam dispostos de coração, e trouxeram fivelas, e pendentes, e anéis, e braceletes, todas as joias de ouro. E cada homem que oferecia, oferecia uma oferta de ouro ao SENHOR.
23 Olúkúlùkù ẹni tí ó ni aṣọ aláró elése àlùkò, òdòdó àti ọ̀gbọ̀ dáradára, tàbí irun ewúrẹ́, awọ àgbò tí a rì ní pupa tàbí awọ màlúù odò, kí ó mú wọn wá.
23 E todo homem que possuía azul, e púrpura, e escarlate, e linho fino, e pelo de cabra, e peles vermelhas de carneiro, e peles de texugo, os trazia.
24 Àwọn tí ó mú ọrẹ fàdákà tàbí idẹ wá, mú ọrẹ wá fún Olúwa, àti olúkúlùkù ẹni tí ó ní igi ṣittimu fún ipa kankan nínú iṣẹ́ mú un wá.
24 Todo aquele que oferecia uma oferta de prata e bronze trazia a oferta do SENHOR; e todo homem que possuía madeira de acácia para qualquer obra de serviço, a trazia.
25 Gbogbo àwọn obìnrin tí ó ní ọgbọ́n ríran owú pẹ̀lú ọwọ́ rẹ̀, kí ó mú èyí ti ó ti ran wá ti aláró, ti elése àlùkò, ti òdòdó tàbí ti ọ̀gbọ̀ dáradára.
25 E todas as mulheres de coração sábio fiavam com as mãos, e traziam o que haviam fiado, tanto de azul, quanto de púrpura, e de escarlate, e de linho fino.
26 Gbogbo àwọn obìnrin tí ó fẹ́, tí ó sì ní ọgbọ́n ń ran òwú irun ewúrẹ́.
26 E todas as mulheres, cujo coração as moveu em sabedoria, fiaram pelo de cabra.
27 Àwọn olórí mú òkúta óníkìsì wá láti tò ó lórí ẹ̀wù efodu àti ìgbàyà.
27 E os governantes trouxeram pedras de ônix, e pedras de engaste, para o éfode, e para o peitoral;
28 Wọ́n sì tún mú olóòórùn àti òróró olifi wá fún títanná àti fún òróró ìtasórí àti fún tùràrí dídùn.
28 e especiarias, e óleo para a luz, e para o óleo da unção, e para o incenso aromático.
29 Gbogbo àwọn ènìyàn Israẹli ọkùnrin àti obìnrin ẹni tí ó fẹ́ mú ọrẹ àtinúwá fún Olúwa fún gbogbo iṣẹ́ tí Olúwa ti pàṣẹ fún wọn láti ṣe nípasẹ̀ Mose.
29 Os filhos de Israel trouxeram uma oferta voluntária ao SENHOR, todo homem e toda mulher cujo coração voluntariamente se moveu a trazer para todo tipo de obra, que o SENHOR ordenara que fosse feita pela mão de Moisés.
30 Nígbà náà ni Mose wí fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Wò ó, Olúwa ti yan Besaleli ọmọ Uri, ọmọ Huri, ti ẹ̀yà Juda,
30 E Moisés disse aos filhos de Israel: Eis que o SENHOR chamou pelo nome Bezalel, o filho de Uri, o filho de Hur, da tribo de Judá,
31 Ó sì ti fi Ẹ̀mí Ọlọ́run kún un, pẹ̀lú ọgbọ́n, òye, ìmọ̀ àti gbogbo onírúurú iṣẹ́ ọnà.
31 e ele o encheu com o Espírito de Deus, em sabedoria, em entendimento, e em conhecimento, e em todo tipo de mão de obra,
32 Láti máa ṣe aláràbarà iṣẹ́ ní ti wúrà, fàdákà àti idẹ,
32 para elaborar obras habilidosas, para trabalhar em ouro, e em prata, e em bronze,
33 láti gbẹ́ òkúta àti láti tò ó, láti fún igi àti láti ṣiṣẹ́ ni gbogbo onírúurú iṣẹ́ ọnà.
33 e em lapidar pedras, para engastá-las, e em esculpir madeira, para fazer todo trabalho esmerado.
34 Ó sì fún òun àti Oholiabu ọmọ Ahisamaki ti ẹ̀yà Dani, ni agbára láti kọ́ àwọn tókù.
34 E ele havia colocado no seu coração que pudesse ensinar, tanto ele quanto Aoliabe, o filho de Aisamaque, da tribo de Dã.
35 Ó sì fi ọgbọ́n kún wọn láti ṣe gbogbo onírúurú iṣẹ́, ti oníṣọ̀nà, ti ayàwòrán, ti aránsọ, ti aláṣọ aláró, ti elése àlùkò, ti òdòdó àti ní ọ̀gbọ̀ dáradára àti ti ahunṣọ, gbogbo èyí tí ọ̀gá oníṣẹ́-ọnà àti ayàwòrán ń ṣe.
35 Encheu-os com sabedoria do coração, para trabalhar em toda obra de mestre, de gravador, e a mais elaborada, e a do bordador, em azul, em púrpura, em escarlate, e em linho fino, e a do tecelão, também a daquele que faz qualquer trabalho, e a daqueles que elaboram trabalho esmerado.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Êxodo 35, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.