Ester 6
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ní òru ọjọ́ náà ọba kò le è sùn; nítorí náà, ó pàṣẹ kí wọn mú ìwé ìrántí wá, àkọsílẹ̀ ìjọba rẹ̀, wọ́n mú un wá wọ́n sì kà á sí létí.
1 Naquela noite o rei não conseguiu dormir, e ele ordenou para trazerem o livro dos registros das crônicas; que foi lido diante do rei.
2 Wọ́n rí àkọsílẹ̀ níbẹ̀ pé Mordekai tí sọ àṣírí Bigitana àti Tereṣi, àwọn ìjòyè ọba méjì tí wọ́n ń ṣọ́ ẹnu-ọ̀nà, tí wọ́n ń gbèrò láti pa ọba Ahaswerusi.
2 E foi achado escrito que Mardoqueu tinha contado sobre Bigtana e Teres, dois dos camareiros do rei, guardas da porta, que procuravam lançar a mão sobre o rei Assuero.
3 Ọba béèrè pé, “Kí ni ọlá àti iyì tí Mordekai ti gbà fún èyí?”
3 E o rei disse: Que honra e dignidade tem sido feita a Mardoqueu por isso? Então, disseram os servos do rei que ministravam a ele: Não há nada feito para ele.
4 Ọba wí pé, “Ta ni ó wà nínú àgbàlá?” Nísinsin yìí, Hamani ṣẹ̀ṣẹ̀ wọ àgbàlá ìta ààfin ni láti sọ fún ọba nípa síso Mordekai lórí igi tí ó ti rì fún un.
4 E o rei disse: Quem está no átrio? Ora, Hamã entrara no átrio externo da casa do rei, para falar ao rei que enforcassem Mardoqueu na forca que lhe tinha preparado.
5 Àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ sì dáhùn pé, “Hamani ni ó wà níbẹ̀ ó dúró sí inú àgbàlá.”
5 E os servos do rei lhe disseram: Eis que Hamã está no átrio. E o rei disse: Deixai-o entrar.
6 Nígbà tí Hamani wọlé, ọba béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ni kí a ṣe fún ọkùnrin tí inú ọba dùn sí láti bu ọlá fún?”
6 Assim, Hamã entrou. E o rei lhe disse: O que será feito para o homem a quem o rei deseja honrar? Ora, Hamã pensou em seu coração: A quem o rei deseja honrar mais do que a mim?
7 Nítorí náà Hamani dá ọba lóhùn pé, “Fún ọkùnrin tí inú ọba dùn sí láti dá lọ́lá,
7 E Hamã respondeu ao rei: Para o homem a quem o rei deseja honrar,
8 jẹ́ kí wọn kí ó mú aṣọ ọba èyí tí ọba ń wọ̀ àti ẹṣin tí ọba máa ń gùn, pẹ̀lú ọ̀kan lára adé ọba kí a fi dé e ní orí.
8 que sejam trazidas as vestimentas reais que o rei usa para vesti-lo, e o cavalo em que o rei monta, e a coroa real que é posta sobre a sua cabeça;
9 Jẹ́ kí a fi aṣọ àti ẹṣin lé ọ̀kan lára àwọn ìjòyè ọba tí ó ga jùlọ lọ́wọ́, kí wọn wọ aṣọ náà fún ọkùnrin tí inú ọba dùn sí láti dá lọ́lá, kí wọn sì sìn ín gun ẹṣin jákèjádò gbogbo ìgboro ìlú, kí wọn máa kéde níwájú rẹ̀ pé, ‘Èyí ni a ṣe fún ọkùnrin náà ẹni tí inú ọba dùn sí láti dá lọ́lá!’ ”
9 e que as suas vestimentas e o cavalo sejam entregues à mão de um dos príncipes mais nobres do rei, para que eles possam tanto vestir o homem a quem o rei deseja honrar, como trazê-lo no lombo do cavalo pela rua da cidade, e proclamem diante dele: Assim será feito ao homem a quem o rei deseja honrar.
10 Ọba pàṣẹ fún Hamani pé, “Lọ lẹ́sẹ̀kan náà. Mú aṣọ náà àti ẹṣin kí o sì ṣe gẹ́gẹ́ bí o ṣe sọ fún Mordekai ará a Júù, ẹni tí ó jókòó sí ẹnu-ọ̀nà ọba. Má ṣe fi ohunkóhun sílẹ̀ nínú ohun tí o ti yàn.”
10 Então, o rei disse a Hamã: Apressa-te e toma as vestes e o cavalo, como disseste, e faz assim ao judeu Mardoqueu, que se assenta junto ao portão do rei; que nada falhe de tudo o que falaste.
11 Bẹ́ẹ̀ ni Hamani ṣe mú aṣọ àti ẹṣin náà. Ó fi wọ Mordekai, Mordekai sì wà lórí ẹṣin jákèjádò gbogbo ìgboro ìlú, ó sì ń kéde níwájú rẹ̀ pé, “Èyí ni a ó ṣe fún ọkùnrin náà ẹni tí inú ọba dùn sí láti dá lọ́lá!”
11 Então, tomou Hamã as vestes e o cavalo, e vestiu Mardoqueu, e o trouxe no lombo do cavalo pela rua da cidade, e proclamou diante dele: Assim será feito ao homem a quem o rei deseja honrar.
12 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí Mordekai padà sí ẹnu-ọ̀nà ọba. Ṣùgbọ́n Hamani sáré lọ ilé, ó sì bo orí rẹ̀ pẹ̀lú ìbànújẹ́,
12 E Mardoqueu retornou ao portão do rei. Já Hamã apressou-se para a sua casa triste, e com a sua cabeça coberta.
13 Hamani sì sọ ohun gbogbo tí ó ṣẹlẹ̀ sí i fún Sereṣi ìyàwó rẹ̀ àti àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀.
13 E Hamã contou a Zeres, sua esposa, e a todos os seus amigos cada coisa que lhe tinha sucedido. Então lhe disseram os seus sábios e sua esposa Zeres: Se Mardoqueu for da semente dos judeus, diante de quem começaste a cair, tu não prevalecerás contra ele, mas certamente cairás diante dele.
14 Bí wọ́n ṣe ń bá a sọ̀rọ̀, àwọn ìwẹ̀fà ọba wọlé, wọ́n sì kán Hamani lójú láti lọ sí ibi àsè tí Esteri ti pèsè.
14 E, enquanto eles ainda estavam falando com ele, chegaram os camareiros do rei, e se apressaram em trazer Hamã ao banquete que Ester havia preparado.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Ester 6, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.