Ester 5

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Ní ọjọ́ kẹta Esteri wọ aṣọ ayaba rẹ̀ ó sì dúró sí inú àgbàlá ààfin, ní iwájú gbọ̀ngàn ọba, ọba jókòó lórí ìtẹ́ ìjọba rẹ̀ nínú gbọ̀ngàn, ó kọjú sí ẹnu-ọ̀nà ìta.
1 Ora, sucedeu que, no terceiro dia, Ester vestiu as suas vestes reais e se pôs de pé no átrio interno da casa do rei, diante da casa do rei; e o rei se assentou sobre o seu trono real na casa real, diante do portão da casa.
2 Nígbà tí ó rí ayaba Esteri tí ó dúró nínú àgbàlá, inú rẹ̀ yọ́ sí i, ọba sì na ọ̀pá aládé wúrà ọwọ́ rẹ̀ sí i. Bẹ́ẹ̀ ni Esteri ṣe súnmọ́ ọn ó sì fi ọwọ́ kan orí ọ̀pá náà.
2 E assim foi, quando o rei viu a rainha Ester de pé no átrio, que ela obteve favor à sua vista; e o rei estendeu a Ester o cetro de ouro que estava na sua mão. Assim, Ester se aproximou, e tocou a extremidade do cetro.
3 Nígbà náà ni ọba béèrè pé, “Kí ni ó dé, ayaba Esteri? Kí ni o fẹ́? Bí ó tilẹ̀ ṣe títí dé ìdajì ọba mi, àní, a ó fi fún ọ.”
3 Então, lhe disse o rei: O que tu desejas, rainha Ester? Qual é a tua petição? Ser-te-á dado até a metade do reino.
4 Esteri sì dáhùn pé, “Bí ó bá tẹ́ ọba lọ́rùn, jẹ́ kí ọba, pẹ̀lú Hamani, wá lónìí sí ibi àsè tí èmi ti pèsè fún un.”
4 E Ester respondeu: Se parecer bom para o rei, que o rei e Hamã venham neste dia ao banquete que preparei para ele.
5 Ọba sì wí pé, “ẹ mú Hamani wá kíákíá, nítorí kí a lè ṣe ohun tí Esteri béèrè fún un.”
5 Então, o rei disse: Fazei com que Hamã se apresse, para que se faça como Ester tem dito. Assim, o rei e Hamã vieram ao banquete que Ester havia preparado.
6 Bí wọ́n ṣe ń mu wáìnì, ọba tún béèrè lọ́wọ́ Esteri, “Báyìí pé: kí ni ẹ̀bẹ̀ rẹ? A ó sì fi fún ọ. Kí ni ìwọ ń béèrè fún? Àní bí ó tilẹ̀ jẹ́ ìdajì ìjọba mi, a ó fi fún ọ.”
6 E o rei disse a Ester no banquete de vinho: Qual é a tua petição? E ser-te-á concedida; e qual é o teu pedido? Até a metade do reino ele te será cumprido.
7 Esteri sì dáhùn, “Ẹ̀bẹ̀ mi àti ìbéèrè mi ni èyí.
7 Então, respondeu Ester, e disse: A minha petição e o meu pedido é:
8 Bí ọba bá fi ojúrere rẹ̀ fún mi, tí ó bá sì tẹ́ ọba lọ́rùn láti gba ẹ̀bẹ̀ mi àti láti mú ìbéèrè mi ṣẹ, jẹ́ kí ọba àti Hamani wá ní ọ̀la sí ibi àsè tí èmi yóò pèsè fún wọn. Nígbà náà ni èmi yóò dáhùn ìbéèrè ọba.”
8 Se tenho achado favor à vista do rei, e se aprouver ao rei conceder a minha petição, e atender ao meu pedido, que o rei e Hamã venham ao banquete que lhes hei de preparar, e farei amanhã como o rei tem dito.
9 Hamani jáde lọ ní ọjọ́ náà pẹ̀lú ayọ̀ àti inú dídùn. Ṣùgbọ́n nígbà tí ó rí Mordekai ní ẹnu-ọ̀nà ọba, ó wòye pé kò dìde tàbí kí ó bẹ̀rù ní iwájú òun, inú bí i gidigidi sí Mordekai.
9 Então, saiu Hamã naquele dia alegre e com o coração contente; mas quando Hamã viu Mardoqueu no portão do rei, que ele não se pôs de pé, nem se moveu por ele, ficou cheio de indignação contra Mardoqueu.
10 Ṣùgbọ́n, Hamani kó ara rẹ̀ ní ìjánu, ó lọ sí ilé.
10 Todavia, Hamã se conteve; e quando ele foi para casa, mandou chamar os seus amigos e sua esposa Zeres.
11 Hamani gbéraga sí wọn nípa títóbi ọ̀rọ̀ rẹ̀, púpọ̀ àwọn ọmọ rẹ̀, àti gbogbo ọ̀nà tí ọba ti bu ọlá fún un àti bí ó ṣe gbé e ga ju àwọn ọlọ́lá àti àwọn ìjòyè tókù lọ.
11 E Hamã lhes contou sobre a glória das suas riquezas, e da multidão dos seus filhos, e de todas as coisas nas quais o rei lhe havia promovido, e como o tinha exaltado acima dos príncipes e dos servos do rei.
12 Hamani tún fi kún un pé, “Kì í ṣe èyí nìkan. Èmi nìkan ni ayaba Esteri pè láti sin ọba wá sí ibi àsè tí ó sè. Bákan náà, ó sì tún ti pè mí pẹ̀lú ọba ní ọ̀la.
12 Hamã disse, além disso: Sim, a rainha Ester, não deixou nenhum homem adentrar ao rei no banquete que ela havia preparado, senão a mim; e também para amanhã estou convidado por ela juntamente com o rei.
13 Ṣùgbọ́n gbogbo èyí kò ì tí ì tẹ́ mi lọ́rùn níwọ̀n ìgbà tí mo bá sì ń rí Mordekai ará a Júù náà tí ó ń jókòó ní ẹnu-ọ̀nà ọba.”
13 Contudo, tudo isso não me satisfaz, enquanto vejo o judeu Mardoqueu assentado junto ao portão do rei.
14 Ìyàwó rẹ̀ Sereṣi àti àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ wí fún un pé, “Ri igi kan, kí ó ga tó ìwọ̀n ẹ̀ṣẹ̀ bàtà márùn le láàdọ́rin, kí o sì sọ fún ọba ní òwúrọ̀ ọ̀la kí ó gbé Mordekai rọ̀ sórí i rẹ̀. Nígbà náà ni ìwọ yóò bá ọba lọ sí ibi àsè pẹ̀lú ayọ̀.” Èrò yí dùn mọ́ Hamani nínú, ó sì ri igi náà.
14 Então, lhe disse sua esposa Zeres, e todos os seus amigos: Que seja feito uma forca de cinquenta côvados, e amanhã fala tu ao rei que Mardoqueu nela seja enforcado; então, adentra tu alegremente ao rei no banquete. E isto agradou Hamã; e ele fez com que a forca fosse feita.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Ester 5, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.