Esdras 8

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Wọ̀nyí ni àwọn olórí ìdílé àti àwọn tí ó fi orúkọ sílẹ̀ pẹ̀lú àwọn tì wọn gòkè pẹ̀lú mi láti Babeli ní àkókò ìjọba Artasasta ọba:
1 Estes são, os chefes dos seus pais, e esta é a genealogia daqueles que subiram comigo de Babilônia, no reinado do rei Artaxerxes.
2 nínú àwọn ọmọ Finehasi:
2 Dos filhos de Fineias: Gérson; dos filhos de Itamar: Daniel; dos filhos de Davi: Hatus.
3 nínú àwọn ọmọ Ṣekaniah;
3 Dos filhos de Secanias e dos filhos de Parós, Zacarias, e com ele foram considerados pelas genealogias dos homens, cento e cinquenta.
4 nínú àwọn ọmọ Pahati-Moabu:
4 Dos filhos de Paate-Moabe: Elioenai, filho de Zeraías, e com ele, duzentos homens.
5 nínú àwọn ọmọ Sattu:
5 Dos filhos de Secanias: o filho de Jaaziel, e com ele trezentos homens.
6 nínú àwọn ọmọ Adini:
6 Dos filhos de Adim: Ebede, o filho de Jônatas, e com ele cinquenta homens.
7 nínú àwọn ọmọ Elamu:
7 E dos filhos de Elão: Jesaías, o filho de Atalias, e com ele setenta homens.
8 nínú àwọn ọmọ Ṣefatia:
8 E dos filhos de Sefatias: Zebadias, o filho de Micael, e com ele oitenta homens.
9 nínú àwọn ọmọ Joabu:
9 Dos filhos de Joabe: Obadias, filho de Jeiel, e com ele duzentos e dezoito homens.
10 nínú àwọn ọmọ Bani:
10 E dos filhos de Selomite: o filho de Josifias, e com ele cento e sessenta homens.
11 nínú àwọn ọmọ Bebai:
11 E dos filhos de Bebai: Zacarias, o filho de Bebai, e com ele vinte e oito homens.
12 nínú àwọn ọmọ Asgadi:
12 E dos filhos de Azgade: Joanã, o filho de Hacatã, e com ele cento e dez homens.
13 nínú àwọn ọmọ Adonikami:
13 E dos últimos filhos de Adonicão, cujos nomes são estes: Elifelete, Jeiel e Semaías, e com eles sessenta homens.
14 nínú àwọn ọmọ Bigfai:
14 Dos filhos também de Bigvai: Utai e Zabude, e com eles setenta homens.
15 Èmi kó wọn jọ pọ̀ si etí odò ti ń sàn lọ sí Ahafa, a pàgọ́ síbẹ̀ fún odidi ọjọ́ mẹ́ta, nígbà ti mo wo àárín àwọn ènìyàn àti àárín àwọn àlùfáà, ń kò rí ọmọ Lefi kankan níbẹ̀.
15 E eu reuni a todos junto ao rio que corre para Aava; e ali nós permanecemos três dias em tendas; e eu vi o povo, e os sacerdotes, e ali não encontrei nenhum dos filhos de Levi.
16 Nígbà náà ni mo pe Elieseri, Arieli, Ṣemaiah, Elnatani, Jaribi, Elnatani, Natani, Sekariah, àti Meṣullamu, tí wọ́n jẹ́ olórí, àti Joiaribu àti Elnatani tí wọ́n jẹ́ onímọ̀ ìjìnlẹ̀,
16 Então eu mandei chamar a Eliézer, a Ariel, a Semaías, e a Elnatã, e a Jaribe, e a Elnatã, e a Natã, e a Zacarias, e a Mesulão, homens principais; também a Joiaribe, e a Elnatã, homens de entendimento.
17 mo sì rán wọn tí àwọn ti àṣẹ sí ọ̀dọ̀ Iddo, tí ó jẹ́ olórí ní ibi ti a ń pè ni Kasifia, mo sì sọ fún wọn ohun tí wọn yóò wí fun Iddo àti àwọn Lefi arákùnrin rẹ̀, tí wọ́n jẹ́ òṣìṣẹ́ tẹmpili ní Kasifia pé, kí wọn mú àwọn ìránṣẹ́ wá sí ọ̀dọ̀ wa fún ilé Ọlọ́run wa.
17 E eu os enviei com mandamento para Ido, o chefe no lugar chamado Casifia, e eu lhes disse o que eles deveriam dizer para Ido, e para os seus irmãos, os netineus, no lugar chamado Casifia, para que eles nos trouxessem ministros para a casa do nosso Deus.
18 Nítorí ọwọ́ àánú Ọlọ́run wa wà lára wa, wọ́n sì mú Ṣerebiah wá fún wa, ẹni tí ó kún ojú òsùwọ̀n láti ìran Mahili, ọmọ Lefi, ọmọ Israẹli, àti àwọn ọmọ Ṣerebiah àti àwọn arákùnrin rẹ̀, wọ́n jẹ́ ọkùnrin méjìdínlógún.
18 E pela boa mão do nosso Deus sobre nós eles nos trouxeram um homem de entendimento, dos filhos de Mali, o filho de Levi, o filho de Israel; e Serebias, com os seus filhos e os seus irmãos, dezoito;
19 Àti Haṣabiah, pẹ̀lú Jeṣaiah láti ìran Merari, pẹ̀lú àwọn arákùnrin rẹ àti àwọn ọmọ wọ́n jẹ́ ogún ọkùnrin.
19 e Hasabias e com ele Jesaías, dos filhos de Merari, os seus irmãos e os seus filhos, vinte;
20 Wọ́n sì tún mú ogún lé nígba (220) àwọn òṣìṣẹ́ tẹmpili wá—àwọn ènìyàn tí Dafidi àti àwọn ìjòyè rẹ̀ gbé kalẹ̀ láti ran àwọn ọmọ Lefi lọ́wọ́. Gbogbo wọn ni a ṣe àkọsílẹ̀ orúkọ wọn.
20 também dos netineus, aos quais Davi e os príncipes haviam indicado para o serviço dos levitas, duzentos e vinte netineus; todos eles foram designados por nome.
21 Níbẹ̀, ní ẹ̀bá odò Ahafa, mo kéde àwẹ̀, kí a ba à le rẹ ara wa sílẹ̀ níwájú Ọlọ́run, kí a sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ fún ìrìnàjò àìléwu fún wa àti àwọn ọmọ wa àti fún gbogbo ohun ìní wa.
21 Então, eu proclamei ali um jejum, junto ao rio de Aava, para que nós pudéssemos nos humilhar diante de Deus, para buscar dele um caminho reto para nós, e para os nossos pequenos, e para toda a nossa fazenda.
22 Mo tijú láti béèrè lọ́wọ́ ọba fún àwọn jagunjagun orí ilẹ̀, àti ti orí ẹṣin láti dáàbò bò wá kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá ní ọ̀nà wa, nítorí àti sọ fún ọba pé, “Ọwọ́ àánú Ọlọ́run wà ní ara gbogbo ẹni tí ó gbé ojú sókè sí i, ṣùgbọ́n ìbínú ńlá rẹ wà lórí ẹni tó kọ̀ ọ́ sílẹ̀.”
22 Pois eu estava envergonhado em requerer do rei uma tropa de soldados e cavaleiros para nos ajudar contra o inimigo pelo caminho; porque nós havíamos falado ao rei, dizendo: A mão do nosso Deus está sobre todos os que o buscam para o bem; mas o seu poder e a sua ira estão contra todos aqueles que o desprezam.
23 Bẹ́ẹ̀ ni a sì gbààwẹ̀, a sì bẹ̀bẹ̀ fún èyí lọ́dọ̀ Ọlọ́run wa, òun sì gbọ́ àdúrà wa.
23 Assim, jejuamos e buscamos o nosso Deus por isto; e ele moveu-se por nós.
24 Nígbà náà ni mo ya àwọn àlùfáà tó jẹ́ aṣáájú méjìlá sọ́tọ̀, pẹ̀lú Ṣerebiah, Haṣabiah àti mẹ́wàá lára àwọn arákùnrin wọn,
24 Então, eu separei doze dos chefes dos sacerdotes, Serebias, Hasabias e com eles dez de seus irmãos,
25 mo sì fi òsùwọ̀n wọn ọrẹ fàdákà àti wúrà àti àwọn ohun èlò tí ọba, àti ti àwọn ìgbìmọ̀, àti ti àwọn ìjòyè, àti ti gbogbo ọmọ Israẹli tí ó wà níbẹ̀, tí wọ́n gbe sílẹ̀ fún ilé Ọlọ́run wa.
25 e pesei-lhes a prata, e o ouro, e os vasos, a saber a oferta para a casa do nosso Deus, a qual tinham oferecido o rei, e os seus conselheiros, e os seus senhores, e todo o Israel presente ali.
26 Mo fi òsùwọ̀n wọn ẹgbẹ̀ta lé láàádọ́ta (650) tálẹ́ǹtì fàdákà, àti ohun èlò fàdákà tí ó wọn ọgọ́rùn-ún tálẹ́ǹtì, ọgọ́rùn-ún tálẹ́ǹtì wúrà,
26 Eu até pesei em suas mãos seiscentos e cinquenta talentos de prata, e em vasos de prata cem talentos, e cem talentos de ouro,
27 ogún ago wúrà tí iye rẹ̀ tó ẹgbẹ̀rún (1,000) dariki, àti ohun èlò idẹ dáradára méjì ti ó ni iye lórí bí i wúrà.
27 também vinte bacias de ouro de mil dracmas, e dois vasos de fino cobre, preciosos como ouro.
28 Mo wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin àti àwọn ohun èlò wọ̀nyí ni a ti yà sí mímọ́ fún Olúwa. Fàdákà àti wúrà sì jẹ́ ọrẹ àtinúwá sí Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín.
28 E eu disse-lhes: Vós sois santos para o ­SENHOR; os vasos também são santos; e a prata e o ouro são uma oferta voluntária ao ­SENHOR Deus dos vossos pais.
29 Ẹ máa tọ́jú wọn dáradára títí ẹ̀yin yóò fi fi òsùwọ̀n wọ̀n wọ́n jáde kúrò ni ilé Olúwa ni Jerusalẹmu ní iwájú àwọn aṣáájú, àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, àti ní iwájú olórí ìdílé gbogbo ni Israẹli.”
29 Atentai, e guardai-os, até que os peseis diante dos chefes dos sacerdotes e dos levitas, e dos chefes dos pais de Israel, em Jerusalém, nas câmaras da casa do ­SENHOR.
30 Nígbà náà ni àwọn àlùfáà àti àwọn Lefi gba fàdákà àti wúrà àti àwọn ohun èlò mímọ́ tí a ti wọ̀n jáde fún kíkó lọ sí ilé Ọlọ́run wa ní Jerusalẹmu.
30 Assim, receberam os sacerdotes e os levitas o peso da prata, e do ouro, e os vasos, para trazê-los a Jerusalém, até a casa do nosso Deus.
31 Ní ọjọ́ kejìlá oṣù kìn-ín-ní ni a gbéra kúrò ní ẹ̀bá odò Ahafa láti lọ sí Jerusalẹmu. Ọwọ́ Ọlọ́run wa wà lára wa, ó sì dáàbò bò wá kúrò lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá àti àwọn adigunjalè ní ọ̀nà wa.
31 Então, nós partimos do rio de Aava, no décimo segundo dia do primeiro mês, para irmos a Jerusalém; e a mão do nosso Deus estava sobre nós, e ele nos livrou da mão do inimigo, e dos que nos armavam ciladas pelo caminho.
32 Bẹ́ẹ̀ ni a gúnlẹ̀ sí Jerusalẹmu, níbi tí a ti sinmi fún ọjọ́ mẹ́ta.
32 E chegamos a Jerusalém, e permanecemos ali três dias.
33 Ní ọjọ́ kẹrin, a wọn ohun èlò fàdákà àti wúrà àti àwọn ohun èlò mímọ lé àlùfáà Meremoti ọmọ Uriah lọ́wọ́, láti inú ilé Ọlọ́run wa, Eleasari ọmọ Finehasi wà pẹ̀lú rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Lefi; Josabadi ọmọ Jeṣua àti Noadiah ọmọ Binnui wà níbẹ̀ pẹ̀lú.
33 Ora, no quarto dia se pesou a prata e o ouro e os vasos na casa do nosso Deus pela mão de Meremote, o filho de Urias, o sacerdote; e com ele estava Eleazar, o filho de Fineias, e com eles estavam Jozabade, o filho de Jesuá, e Noadias, o filho de Binui, levitas;
34 Gbogbo nǹkan ni a kà, tí a sì wọ̀n, gbogbo iye ìwọ̀n ni a sì ṣe àkọsílẹ̀ rẹ̀ sínú ìwé ní ìgbà náà.
34 por número e por peso de cada um; e todo o peso foi escrito naquele momento.
35 Nígbà náà ni àwọn ìgbèkùn tí ó ti padà láti ilẹ̀ àjèjì rú ẹbọ sísun sí Ọlọ́run Israẹli: akọ màlúù méjìlá fún gbogbo Israẹli, àgbò mẹ́rìndínlọ́gọ́rùn-ún, ọ̀dọ́-àgùntàn mẹ́tàdínlọ́gọ́rin, àti òbúkọ méjìlá fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀. Gbogbo èyí jẹ́ ẹbọ sísun sí Olúwa.
35 Os filhos do cativeiro que tinham voltado do exílio, ofereceram ofertas queimadas ao Deus de Israel, doze novilhos por todo o Israel, noventa e seis carneiros, setenta e sete cordeiros, doze bodes como uma oferta pelo pecado; tudo isso foi uma oferta queimada ao ­SENHOR.
36 Wọ́n sì jíṣẹ́ àṣẹ ọba fún àwọn ìjòyè àti àwọn baálẹ̀ agbègbè Eufurate, wọ́n sì ṣe ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ènìyàn àti ilé Ọlọ́run.
36 E entregaram os decretos do rei aos tenentes do rei, e aos governadores deste lado do rio; e eles apoiaram o povo, e a casa de Deus.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Esdras 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.