Esdras 5
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Nígbà náà wòlíì Hagai àti wòlíì Sekariah, láti ìran Iddo, sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí àwọn ará Júù ní Juda àti Jerusalẹmu ní orúkọ Ọlọ́run Israẹli tí ẹ̀mí rẹ̀ ń bẹ lára wọn.
1 Então, os profetas, Ageu e Zacarias, filho de Ido, profetizaram aos judeus que estavam em Judá e em Jerusalém; em nome do Deus de Israel, lhes profetizaram.
2 Nígbà náà Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli àti Jeṣua ọmọ Josadaki gbáradì fún iṣẹ́ àti tún ilé Ọlọ́run ní Jerusalẹmu kọ́. Àwọn wòlíì Ọlọ́run sì wà pẹ̀lú wọn, tí wọ́n ń ràn wọ́n lọ́wọ́.
2 Então, levantou-se Zorobabel, o filho de Sealtiel, e Jesuá, o filho de Jozadaque, e começaram a edificar a casa de Deus a qual está em Jerusalém; e com eles estavam os profetas de Deus lhes ajudando.
3 Ní àkókò náà Tatenai, baálẹ̀ ti agbègbè Eufurate àti Ṣetar-bosnai àti àwọn ẹgbẹgbẹ́ wọn lọ sí ọ̀dọ̀ wọn. Wọ́n sì béèrè pé, “Ta ni ó fún un yín ní àṣẹ láti tún tẹmpili yìí kọ́ àti láti tún odi yìí mọ?”
3 Ao mesmo tempo vieram até eles, Tatenai, governador deste lado do rio, e Setar-Bozenai, e os seus companheiros, e assim lhes disseram: Quem vos ordenou a edificar esta casa, e a construir esta muralha?
4 Wọ́n sì tún béèrè pé, “Kí ni orúkọ àwọn ọkùnrin tí ó ń kọ́ ilé yìí?”
4 Então nós lhes dissemos desta forma: Quais são os nomes dos homens que fazem esta edificação?
5 Ṣùgbọ́n ojú Ọlọ́run wọn wà lára àwọn àgbàgbà Júù, wọn kò sì dá wọn dúró títí ìròyìn yóò fi dè ọ̀dọ̀ Dariusi kí wọ́n sì gba èsì tí àkọsílẹ̀ láti ọ̀dọ̀ rẹ̀.
5 Porém os olhos de Deus estavam sobre os anciãos dos judeus, para que eles não pudessem fazê-los cessar, até que a questão viesse até Dario; e, então, eles retornaram a resposta por carta acerca desta questão.
6 Èyí ni ẹ̀dà lẹ́tà tí Tatenai, olórí agbègbè Eufurate àti Ṣetar-bosnai àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn. Àwọn olóyè ti agbègbè Eufurate, fi ránṣẹ́ sí ọba Dariusi.
6 A cópia da carta que Tatenai, governador deste lado do rio, e Setar-Bozenai, e os seus companheiros, os afarsaquitas, os quais estavam deste lado do rio, enviaram ao rei Dario;
7 Ìròyìn tí wọ́n fi ránṣẹ́ sí i kà báyìí pé,
7 enviaram-lhe uma carta, na qual estava escrito assim: Para Dario, o rei, toda a paz.
8 Kí ọba kí ó mọ̀ pé a lọ sí ẹ̀kún Juda, sí tẹmpili Ọlọ́run tí ó tóbi. Àwọn ènìyàn náà ń kọ́ ọ pẹ̀lú àwọn òkúta ńlá ńlá àti pẹ̀lú fífi àwọn igi sí ara ògiri. Wọ́n ṣe iṣẹ́ náà pẹ̀lú àìsimi, ó sì ń ní ìtẹ̀síwájú kíákíá lábẹ́ ìṣàkóso wọn.
8 Seja notório ao rei, que nós fomos à província da Judeia, à casa do grande Deus, a qual está edificada com grandes pedras, e a madeira está lançada nas paredes, e esta obra avança com rapidez, e prospera nas suas mãos.
9 A bi àwọn àgbàgbà, a sì fi ọ̀rọ̀ wá wọn lẹ́nu wò pé, “Ta ni ó fún un yín ní àṣẹ láti tún ilé Olúwa yìí kọ́ àti láti tún odi rẹ̀ mọ?”
9 Então, nós perguntamos àqueles anciãos, e assim lhes dissemos: Quem vos ordenou a edificar esta casa, e a levantar estas paredes?
10 A sì tún béèrè orúkọ wọn pẹ̀lú, kí a lè kọ àwọn orúkọ àwọn olórí wọn sílẹ̀ kí ẹ ba à le mọ ọ́n.
10 Nós também perguntamos os seus nomes, para certificar-te, para que pudéssemos escrever os nomes dos homens que eram os seus chefes.
11 Èyí ni ìdáhùn tí wọ́n fún wa:
11 E assim eles retornaram com a resposta, dizendo: Nós somos os servos do Deus do céu e terra, e edificamos a casa que há muitos anos foi edificada, a qual um grande rei de Israel edificou e estabeleceu.
12 Ṣùgbọ́n nítorí tí àwọn baba wa mú Ọlọ́run ọ̀run bínú, ó fi wọ́n lé Nebukadnessari ti Kaldea, ọba Babeli lọ́wọ́, ẹni tí ó run tẹmpili Olúwa yìí tí ó sì kó àwọn ènìyàn náà padà sí Babeli.
12 Mas depois que nossos pais provocaram à ira o Deus do céu, ele os deu na mão de Nabucodonosor, o rei de Babilônia, o caldeu, que destruiu esta casa, e levou o povo consigo para Babilônia.
13 “Ṣùgbọ́n ní ọdún kìn-ín-ní ìjọba Kirusi ọba Babeli, ọba Kirusi pàṣẹ pé kí a tún ilé Ọlọ́run yìí kọ́.
13 Todavia, no primeiro ano de Ciro, o rei de Babilônia, o mesmo rei Ciro editou um decreto para edificar esta casa de Deus.
14 Òun tilẹ̀ kò jáde láti inú tẹmpili ní Babeli fàdákà àti ohun èlò wúrà ilé Ọlọ́run, èyí tí Nebukadnessari kó láti inú tẹmpili ní Jerusalẹmu wá sí inú tẹmpili ní Babeli. Ọba Kirusi kó wọn fún ọkùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Ṣeṣbassari, ẹni tí ó ti yàn gẹ́gẹ́ bí i baálẹ̀,
14 E também os vasos de ouro e prata da casa de Deus, os quais Nabucodonosor retirou do templo que estava em Jerusalém, e os trouxe para dentro do templo de Babilônia, o rei Ciro os retirou do templo de Babilônia, e eles foram entregues a um cujo nome era Sesbazar, ao qual ele havia feito governador;
15 ó sì sọ fún un pé, ‘Kó àwọn ohun èlò yìí kí o lọ, kí o sì kó wọn sí inú ilé Olúwa ní Jerusalẹmu, kí ẹ sì tún ilé Ọlọ́run kọ́ sí ipò o rẹ̀.’
15 e disse-lhe: Toma estes vasos, vai, leva-os para dentro do templo que está em Jerusalém, e deixa com que a casa de Deus seja edificada no seu lugar.
16 “Nígbà náà ni Ṣeṣbassari náà wá, ó sí fi ìpìlẹ̀ ilé Ọlọ́run tí ó wá ní Jerusalẹmu lélẹ̀, láti ìgbà náà àní títí di ìsinsin yìí ni o ti n bẹ ní kíkọ́ ṣùgbọ́n, kò sí tí ì parí tán.”
16 Então veio o mesmo Sesbazar, e lançou os fundamentos da casa de Deus a qual está em Jerusalém; e desde aquele tempo até agora ela tem estado em edificação, e ainda não está acabada.
17 Nísinsin yìí tí ó bá tẹ́ ọba lọ́rùn, ẹ jẹ́ kí a ṣe ìwádìí nínú ìwé ìrántí ní ilé ìṣúra ọba ní Babeli láti rí bí ọba Kirusi fi àṣẹ lélẹ̀ lóòótọ́ láti tún ilé Ọlọ́run yìí kọ́ ní Jerusalẹmu. Nígbà náà jẹ́ kí ọba kó fi ìpinnu rẹ̀ lórí ọ̀rọ̀ yìí ránṣẹ́ sí wa.
17 Agora, portanto, se parecer bom ao rei, que ali seja feita uma investigação na casa do tesouro do rei, que está em Babilônia, para ver se é verdade que foi feito um decreto da parte do rei Ciro, para edificar esta casa de Deus em Jerusalém, e sobre esta questão que o rei nos envie a sua consideração.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Esdras 5, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.