Esdras 1

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Ní ọdún kìn-ín-ní Kirusi, ọba Persia, kí a lè mú ọ̀rọ̀ Olúwa tí Jeremiah sọ ṣẹ, Olúwa ru ọkàn Kirusi ọba Persia sókè láti ṣe ìkéde jákèjádò gbogbo agbègbè ìjọba rẹ̀, kí ó sì ṣe àkọsílẹ̀ rẹ̀ pé,
1 Ora, no primeiro ano de Ciro, rei da Pérsia, para que se cumprisse a palavra do SENHOR, pela boca de Jeremias, o SENHOR suscitou o espírito de Ciro, rei da Pérsia, para que ele fizesse uma proclamação ao longo de todo o seu reino, e também por escrito, dizendo:
2 “Èyí ni ohun tí Kirusi ọba Persia wí pé:
2 Assim diz Ciro, rei da Pérsia: O SENHOR Deus do céu tem me dado todos os reinos da terra; e ele me encarregou de edificar-lhe uma casa em Jerusalém, a qual está em Judá.
3 Ẹnikẹ́ni nínú àwọn ènìyàn rẹ̀ láàrín yín—kí Ọlọ́run rẹ̀ wà pẹ̀lú rẹ̀, kí ó sì gòkè lọ sí Jerusalẹmu tí ó wà ní Juda, láti kọ́ tẹmpili Olúwa Ọlọ́run Israẹli, Ọlọ́run tí ó wà ní Jerusalẹmu.
3 Quem há entre vós de todo o seu povo? O seu Deus seja com ele, e deixai-o subir até Jerusalém, a qual está em Judá, e edificar a casa do SENHOR Deus de Israel (ele é o Deus) a qual está em Jerusalém.
4 Kí àwọn ènìyàn ní ibikíbi tí ẹni náà bá ń gbé kí ó fi fàdákà àti wúrà pẹ̀lú ohun tí ó dára àti ẹran ọ̀sìn, pẹ̀lú ọrẹ àtinúwá ràn án lọ́wọ́ fún tẹmpili Ọlọ́run ní Jerusalẹmu.’ ”
4 E todo aquele que permanecer em qualquer lugar onde ele pousar, que os homens do seu lugar o ajudem com prata, e com ouro, e com bens, e com animais, além da oferta voluntária para a casa de Deus que está em Jerusalém.
5 Nígbà náà àwọn olórí ìdílé Juda àti Benjamini àti àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi—olúkúlùkù ẹni tí Ọlọ́run ti fọwọ́ tọ́ ọkàn rẹ̀—múra láti gòkè lọ láti kọ ilé Olúwa ní Jerusalẹmu.
5 Então, levantou-se o chefe dos pais de Judá e de Benjamim, e os sacerdotes, e os levitas, com todos aqueles cujo espírito Deus havia suscitado, para subirem e edificar a casa do SENHOR, a qual está em Jerusalém.
6 Gbogbo àwọn aládùúgbò wọn ràn wọ́n lọ́wọ́ pẹ̀lú ohun èlò ti fàdákà àti wúrà, pẹ̀lú onírúurú ohun ìní àti ẹran ọ̀sìn àti pẹ̀lú àwọn ẹ̀bùn iyebíye, ní àfikún si gbogbo àwọn ọrẹ àtinúwá.
6 E todos aqueles que estavam junto a eles fortaleciam as suas mãos com vasos de prata, com ouro, com bens, e com animais, e com coisas preciosas, além de tudo o que era voluntariamente oferecido.
7 Ní àfikún, ọba Kirusi mú àwọn ohun èlò tí ó jẹ́ ti ilé Olúwa jáde wá, tí Nebukadnessari ti kó lọ láti Jerusalẹmu tí ó sì ti kó sí ilé òrìṣà rẹ̀.
7 Além disso, o rei Ciro trouxe os vasos da casa do SENHOR, os quais Nabucodonosor havia trazido de Jerusalém, e havia colocado na casa dos seus deuses;
8 Kirusi ọba Persia pàṣẹ fún Mitredati olùṣọ́ ilé ìṣúra láti kó wọn jáde, ó sì kà wọ́n fún Ṣeṣbassari ìjòyè Juda.
8 estes, Ciro, o rei da Pérsia, trouxe pela mão de Mitredate, o tesoureiro, e os numerou para Sesbazar, príncipe de Judá.
9 Èyí ni iye wọn.
9 E este é o número deles: trinta travessas de ouro, mil travessas de prata, vinte e nove facas,
10 Ọgbọ̀n àdému wúrà
10 trinta bacias de ouro, quatrocentas e dez bacias de prata de segunda ordem, e mil outros vasos.
11 Gbogbo ohun èlò wúrà àti ti fàdákà ní àpapọ̀ jẹ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún ó lé irinwó (5,400).
11 Todos os vasos de ouro e prata eram cinco mil e quatrocentos. Todos estes trouxe Sesbazar, quando os do cativeiro foram trazidos de Babilônia para Jerusalém.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Esdras 1, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.