Eclesiastes 8
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ta ni ó dàbí ọlọ́gbọ́n ènìyàn?
1 Quem é como o homem sábio? E quem sabe a interpretação das coisas? A sabedoria do homem faz brilhar a sua face, e o vigor da sua face é alterado.
2 Mo sọ wí pé, pa òfin ọba mọ́, nítorí pé, ìwọ ti ṣe ìbúra níwájú Ọlọ́run.
2 Eu aconselho que observes o mandamento do rei, e isso em consideração ao juramento de Deus.
3 Má ṣe jẹ́ kí ojú kán ọ láti kúrò ní iwájú ọba, má ṣe dúró nínú ohun búburú, nítorí yóò ṣe ohunkóhun tí ó bá tẹ́ ẹ lọ́rùn.
3 Não te apresses a sair da sua vista, nem persistas em alguma coisa má, porque ele faz tudo do modo como quer.
4 Níwọ́n ìgbà tí ọ̀rọ̀ ọba ni àṣẹ, ta ni ó le è sọ fún un wí pé, “Kí ni ìwọ ń ṣe?”
4 Porque a palavra de um rei tem poder; e quem lhe dirá: Que fazes?
5 Ẹnikẹ́ni tí ó bá pa àṣẹ rẹ̀ mọ́, kò ní wá sí ìpalára kankan,
5 Quem guardar o mandamento não sentirá mal algum; e o coração do sábio discernirá o tempo e o juízo.
6 Ohun gbogbo ni ó ní àsìkò àti ọ̀nà tí ó tọ́ láti ṣe,
6 Porque para todo o propósito há tempo e juízo; porquanto a miséria do homem é grande sobre ele.
7 Níwọ́n ìgbà tí kò sí ẹni tí ó mọ ọjọ́-ọ̀lá,
7 Porque ele não sabe o que há de ser; porquanto quem lhe dirá quando há de ser?
8 Kò sí ẹni tí ó lágbára lórí afẹ́fẹ́ láti gbà á dúró,
8 Nenhum homem há que tenha poder sobre o espírito, para o reter; nem tem ele poder no dia da morte; nem se liberar em tempo de guerra; nem a maldade livrará aqueles que a possuem.
9 Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni mo ti rí, tí mo sì ń múlò ní ọkàn mi sí gbogbo iṣẹ́ tí a ti ṣe lábẹ́ oòrùn. Ìgbà kan wà tí ẹnìkan ń ṣe olórí àwọn tókù fún ìpalára rẹ̀.
9 Tudo isto eu tenho visto, e apliquei o meu coração a toda a obra que se faz debaixo do sol; há um tempo em que um homem governa sobre outro homem, para o seu próprio dano.
10 Nígbà náà ni mo tún rí ìsìnkú ènìyàn búburú—àwọn tí wọ́n máa ń wá tí wọ́n sì ń lọ láti ibi mímọ́ kí wọn sì gba ìyìn ní ìlú tàbí tí wọ́n ti ṣe èyí. Eléyìí pẹ̀lú kò ní ìtumọ̀.
10 E então eu vi os ímpios sepultados, aqueles que tinham entrado e saído do lugar santo; e eles foram esquecidos na cidade em que assim fizeram; isto também é vaidade.
11 Nígbà tí a kò bá tètè ṣe ìdájọ́ fún ẹlẹ́ṣẹ̀ kíákíá, ọkàn àwọn ènìyàn a máa kún fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìmọ̀ láti ṣe ibi.
11 Porque não se executa rapidamente uma sentença sobre a má obra, então o coração dos filhos dos homens está inteiramente disposto a fazer o mal.
12 Bí ènìyàn búburú tó dẹ́ṣẹ̀ nígbà ọgọ́rùn-ún tilẹ̀ wà láààyè fún ìgbà pípẹ́, mo mọ̀ wí pé yóò dára fún ẹni tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run, tí ó bẹ̀rù níwájú rẹ̀.
12 Embora o pecador pratique o mal cem vezes, e os seus dias se prolonguem, ainda assim eu sei com certeza que bem sucede aos que temem a Deus, aos que temem diante dele.
13 Bẹ́ẹ̀ ni kì yóò dára fún ènìyàn búburú, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò fa ọjọ́ rẹ̀ gún tí ó dà bí òjìji, nítorí tí kò bẹ̀rù níwájú Ọlọ́run.
13 Porém, o ímpio não irá bem, e ele não lhe prolongará os dias, que são como a sombra; porque ele não teme diante de Deus.
14 Ohun mìíràn tún wà tí kò ní ìtumọ̀, tí ó ń ṣẹlẹ̀ láyé olódodo tí ó ń gba ohun tí ó tọ́ sí òṣìkà àti ènìyàn búburú tí ó ń gba ohun tí ó tọ́ sí olódodo. Mo sọ wí pé eléyìí gan an kò ní ìtumọ̀.
14 Há uma vaidade que se faz sobre a terra: há homens justos a quem sucede de acordo com as obras dos ímpios, e também há homens ímpios a quem sucede de acordo com as obras dos justos. Eu digo que isto também é vaidade.
15 Nítorí náà mo kan sáárá sí ìgbádùn ayé, nítorí pé kò sí ohun tí ó dára fún ènìyàn ní abẹ́ oòrùn ju pé kí ó jẹ, kí ó mu, kí inú rẹ̀ sì dùn lọ. Nígbà náà ni ìdùnnú yóò bá a rìn nínú iṣẹ́ ẹ rẹ̀, ní gbogbo ọjọ́ ayé ti Ọlọ́run tí fi fún un lábẹ́ oòrùn.
15 Então eu elogiei a alegria, porque o homem não tem nada melhor debaixo do sol do que comer, beber e alegrar-se; porque isso o acompanhará no seu trabalho nos dias da sua vida, que Deus lhe dá debaixo do sol.
16 Nígbà tí mo lo ọkàn mi láti mọ ọgbọ́n àti láti wo wàhálà ènìyàn ní ayé.
16 Quando apliquei o meu coração a conhecer a sabedoria, e a ver o negócio que é realizado sobre a terra (pois também há que, nem o dia nem a noite dorme com os seus olhos);
17 Nígbà náà ni mo rí gbogbo ohun tí Ọlọ́run tí ṣe, kò sí ẹnìkan tí ó le è mòye ohun tí ó ń lọ lábẹ́ oòrùn. Láìbìkítà gbogbo ìyànjú rẹ̀ láti wá rí jáde, ènìyàn kò le è mọ ìtumọ̀ rẹ̀, kódà bí ọlọ́gbọ́n ènìyàn rò wí pé òun mọ̀ ọ́n, kò le è ní òye rẹ̀ ní pàtó.
17 então contemplei toda a obra de Deus, que o homem não pode descobrir a obra que se faz debaixo do sol; por mais que trabalhe o homem para a descobrir, contudo, ele não a encontrará; e embora o homem sábio pense que a conhece, ainda assim ele não poderá encontrá-la.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Eclesiastes 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.