Eclesiastes 5
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ṣọ́ ìrìn rẹ nígbà tí o bá lọ sí ilé Ọlọ́run. Kí ìwọ kí ó sì múra láti gbọ́ ju àti ṣe ìrúbọ aṣiwèrè, tí kò mọ̀ wí pé òun ń ṣe búburú.
1 Guarda o teu pé, quando entrares na casa de Deus; e esteja mais pronto a ouvir do que a oferecer o sacrifício de tolos, porque eles não sabem que fazem mal.
2 Má ṣe yára pẹ̀lú ẹnu un rẹ,
2 Não te precipites com a tua boca, nem o teu coração se apresse a pronunciar qualquer coisa diante de Deus; porque Deus está no céu, e tu estás sobre a terra; portanto, que sejam poucas as tuas palavras.
3 Gẹ́gẹ́ bí àlá tí ń wá, nígbà tí ìlépa púpọ̀ wà,
3 Porque o sonho vem através da multidão de negócios, e a voz do tolo é conhecida pela multidão de palavras.
4 Nígbà tí o bá ṣe ìlérí sí Ọlọ́run, má ṣe pẹ́ ní mímúṣẹ, kò ní inú dídùn sí òmùgọ̀, mú ìlérí rẹ sẹ.
4 Quando fizeres algum voto a Deus, não tardes em pagá-lo; porque ele não se agrada de tolos; o que votares, paga-o.
5 Ó sàn láti má jẹ́ ẹ̀jẹ́, ju wí pé kí a jẹ́ ẹ̀jẹ́ kí a má mu ṣẹ lọ.
5 Melhor é que tu não prometas, do que prometeres e não pagar.
6 Má ṣe jẹ́ kí ẹnu rẹ tì ọ́ sínú ẹ̀ṣẹ̀. Má sì ṣe sọ fún òjíṣẹ́ ilé ìsìn pé, “Àṣìṣe ni ẹ̀jẹ́ mi.” Kí ló dé tí Ọlọ́run fi le è bínú sí ọ, kí ó sì ba iṣẹ́ ọwọ́ rẹ jẹ́?
6 Não sofra a tua boca fazendo pecar a tua carne, nem digas diante do anjo que foi erro; por que se iraria Deus contra a tua voz, e destruiria a obra das tuas mãos?
7 Asán ni ọ̀pọ̀ àlá àti ọ̀rọ̀ púpọ̀. Nítorí náà dúró nínú ìbẹ̀rù Ọlọ́run.
7 Porque na multidão dos sonhos e nas muitas palavras, há também diversas vaidades; porém, teme tu a teu Deus.
8 Bí o bá rí tálákà tí wọ́n ń ni lára ní ojú púpọ̀, tí a sì ń fi òtítọ́ àti ẹ̀tọ́ rẹ̀ dù ú, má ṣe jẹ́ kí ó yà ọ́ lẹ́nu láti rí irú nǹkan bẹ́ẹ̀, nítorí pé ẹni tí ó wà ní ipò gíga máa ń mọ́ òṣìṣẹ́ tí ó wà lábẹ́ rẹ̀ lójú ni, síbẹ̀ àwọn kan sì wà tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn méjèèjì.
8 Se vires em alguma província a opressão do pobre, e a violenta perversão do julgamento e da justiça, não te admires de tal acontecimento; pois aquele que é mais alto do que aquele que é considerado o mais alto; há ainda outros mais altos do que eles.
9 Gbogbo wọn ni ó ń pín èrè tí wọ́n bá rí lórí ilẹ̀, àní ọba pàápàá ń jẹ èrè lórí oko.
9 Ademais, o lucro da terra é para todos; até o próprio rei se serve do campo.
10 Ẹni tí ó bá ní ìfẹ́ owó kì í ní owó ànító,
10 Aquele que ama a prata não se satisfará com a prata; e nem aquele que ama a abundância com o aumento; isto também é vaidade.
11 Bí ẹrù bá ti ń pọ̀ sí i,
11 Quando aumenta os bens, multiplicam-se os que os comem; que proveito têm os seus donos além de contemplá-los com os seus olhos?
12 Oorun alágbàṣe a máa dùn,
12 O sono de um trabalhador é doce, quer coma pouco quer muito; mas a fartura do rico não o permite dormir.
13 Mo ti rí ohun tí ó burú gidigidi lábẹ́ oòrùn
13 Há um mal doloroso que vi debaixo do sol, a saber, as riquezas que os seus donos guardam para o seu próprio dano.
14 Tàbí ọrọ̀ tí ó sọnù nípa àìrí ojúrere,
14 Mas estas riquezas perecem pelo mau trabalho, e havendo um filho, nada lhe fica na sua mão.
15 Ìhòhò ni ènìyàn wá láti inú ìyá rẹ̀,
15 Assim como ele nasceu do ventre de sua mãe, nu tornará, assim como veio; e nada tomará do seu trabalho, que ele possa levar na sua mão.
16 Ohun búburú gbá à ni eléyìí pàápàá.
16 E isto também é um grave mal, que em todos os pontos, justamente como veio, assim ele há de ir; e que proveito ele tem em trabalhar para o vento?
17 Ó ń jẹ nínú òkùnkùn ní gbogbo ọjọ́ ọ rẹ̀,
17 E, em todos os seus dias também come em trevas, e tem muita angústia e ira por causa de sua enfermidade.
18 Nígbà náà ni mo wá rí i dájú pé, ó dára, ó sì tọ̀nà fún ènìyàn láti jẹ, kí ó mu, kí ó sì ní ìtẹ́lọ́rùn nínú iṣẹ́ wàhálà rẹ̀ lábẹ́ oòrùn, ní àkókò ọjọ́ ayé díẹ̀ tí Ọlọ́run ti fi fún un, nítorí ìpín rẹ̀ ni èyí.
18 Eis aqui o que eu vi: uma coisa boa e bela é comer e beber, e desfrutar cada um do bem de todo o trabalho que realizou debaixo do sol, todos os dias de vida que Deus lhe deu, porque esta é a sua porção.
19 Síwájú sí, nígbà tí Ọlọ́run fún ẹnikẹ́ni ní ọrọ̀ àti ohun ìní, tí ó sì fún un lágbára láti gbádùn wọn, láti gba ìpín rẹ̀ kí inú rẹ̀ sì dùn sí iṣẹ́ rẹ—ẹ̀bùn Ọlọ́run ni èyí.
19 E a todo o homem, também a quem Deus deu riquezas e bens, e lhe deu poder para delas comer e tomar a sua porção, e gozar do seu trabalho; isto é dádiva de Deus.
20 Ó máa ń ronú lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan nípa ọjọ́ ayé rẹ lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan nítorí pé Ọlọ́run ń pa á mọ́ pẹ̀lú inú dídùn ní ọkàn rẹ̀.
20 Porque ele não há de lembrar muito dos dias da sua vida; porquanto Deus lhe responde na alegria de seu coração.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Eclesiastes 5, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.