Eclesiastes 3

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Àsìkò wà fún ohun gbogbo,
1 Para cada coisa há um tempo, e um tempo para todo o propósito debaixo do céu.
2 Ìgbà láti bí àti ìgbà kíkú,
2 Um tempo para nascer, e um tempo para morrer; um tempo para plantar, e tempo para arrancar o que se plantou;
3 Ìgbà láti pa àti ìgbà láti mú láradá
3 um tempo para matar, e um tempo para curar; um tempo para destruir, e um tempo para construir;
4 Ìgbà láti sọkún àti ìgbà láti rín ẹ̀rín
4 um tempo para chorar, e um tempo para rir; um tempo para prantear, e um tempo para dançar;
5 ìgbà láti tú òkúta ká àti ìgbà láti ṣà wọ́n jọ
5 um tempo para espalhar pedras, e um tempo para ajuntar pedras; um tempo para abraçar, e um tempo para evitar de abraçar;
6 ìgbà láti wá kiri àti ìgbà láti ṣàì wá kiri
6 um tempo para adquirir, e um tempo para perder; um tempo para guardar, e um tempo para lançar fora;
7 ìgbà láti ya àti ìgbà láti rán
7 um tempo para rasgar, e um tempo para costurar; um tempo para manter silêncio, e um tempo para falar;
8 ìgbà láti ní ìfẹ́ àti ìgbà láti kórìíra
8 um tempo para amar, e um tempo para odiar; um tempo para guerrear, e um tempo para a paz.
9 Kí ni òṣìṣẹ́ jẹ ní èrè nínú wàhálà rẹ̀?
9 Que benefício tem o trabalhador naquilo em que trabalha?
10 Mo ti rí àjàgà tí Ọlọ́run gbé lé ọmọ ènìyàn.
10 Tenho visto o trabalho que Deus deu aos filhos dos homens, para nele serem exercidos.
11 Ó ti ṣe ohun gbogbo dáradára ní àsìkò tirẹ̀, ó sì ti fi èrò nípa ayérayé sí ọkàn ọmọ ènìyàn, síbẹ̀, wọn kò le ṣe àwárí ìdí ohun tí Ọlọ́run ti ṣe láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin.
11 Tudo ele fez formoso em seu tempo; também pôs o mundo em seus corações, para que nenhum homem possa descobrir a obra que Deus fez desde o princípio até ao fim.
12 Mo mọ̀ wí pé kò sí ohun tí ó dára fún ènìyàn ju pé kí inú wọn dùn kí wọn sì ṣe rere níwọ̀n ìgbà tí wọ́n sì wà láààyè.
12 Eu sei que não há prazer nisso, a não ser que o homem se alegre e faça o bem em sua vida;
13 Wí pé: kí olúkúlùkù le è jẹ, kí wọn sì mu, kí wọn sì rí ìtẹ́lọ́rùn nínú gbogbo iṣẹ́ wọn ẹ̀bùn Ọlọ́run ni èyí jẹ́.
13 e também que todo o homem coma e beba, e goze do bem de todo o seu trabalho; isto é a dádiva de Deus.
14 Mo mọ̀ wí pé ohun gbogbo tí Ọlọ́run ṣe ni yóò wà títí láé, kò sí ohun tí a lè fi kún un tàbí kí a yọ kúrò nínú rẹ̀. Ọlọ́run ṣe èyí kí ènìyàn le è ní ìbẹ̀rù rẹ̀ ni.
14 Eu sei que tudo quanto Deus faz será para sempre; nada se lhe deve acrescentar, e nada se lhe deve tirar; e isto Deus faz, para que o homem tema diante dele.
15 Ohun tí ó wà ti wà tẹ́lẹ̀,
15 O que é, já existiu; e o que está para ser, também já existiu; e Deus requer aquilo que passou.
16 Mo sì tún rí ohun mìíràn ní
16 E além do mais, vi debaixo do sol que no lugar do juízo havia impiedade, e no lugar da justiça havia iniquidade.
17 Mo wí nínú ọkàn mi,
17 Eu disse em meu coração: Deus julgará o justo e o ímpio; porquanto há um tempo para todo o propósito e para toda a obra.
18 Mo tún rò pé “Ọlọ́run ń dán wa wò láti fihàn wá wí pé bí ẹranko ni ènìyàn rí.
18 Eu disse em meu coração, a respeito da condição dos filhos dos homens, que Deus os manifestaria, para que assim pudessem ver que são em si mesmos animais.
19 Ó ní láti jẹ́ ohun ìrántí pé ìpín ènìyàn rí bí i tẹranko ìpín kan náà ń dúró dè wọ́n. Bí ọ̀kan ti ń kú náà ni èkejì yóò kú. Àwọn méjèèjì ni irú èémí kan náà, ènìyàn kò sàn ju ẹranko lọ, nítorí pé asán ni yíyè jẹ́ fún wọn.
19 Porque o que recai sobre os filhos dos homens, também recai sobre os animais, e lhes sucede a mesma coisa; assim como morre um, também morre o outro; porque todos têm o mesmo fôlego, de modo que o homem não tem preeminência sobre um animal; porquanto tudo é vaidade.
20 Ibìkan náà ni gbogbo wọn ń lọ, wọ́n wá láti inú erùpẹ̀, inú erùpẹ̀ náà ni wọn yóò tún padà sí.
20 Todos vão para um lugar; todos são do pó, e todos voltam ao pó.
21 Ta ni ó mọ̀ bóyá ẹ̀mí ènìyàn ń lọ sí òkè tí ẹ̀mí ẹranko sì ń lọ sí ìsàlẹ̀ nínú ilẹ̀ ni?”
21 Quem conhece o espírito do homem que vai para cima, e o espírito do animal que vai para baixo da terra?
22 Nígbà náà, ni mo wá rí i wí pé, kò sí ohun tí ó sàn fún ènìyàn ju kí ó gbádùn iṣẹ́ rẹ̀, nítorí pé ìpín tirẹ̀ ni èyí. Tàbí ta ni ó le è mú kí ó rí ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀ kò sí!
22 Assim percebo que não há coisa melhor para o homem do que alegrar-se nas suas próprias obras, porque essa é a sua porção; porque quem o fará voltar para ver o que será depois dele?

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Eclesiastes 3, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.