Deuteronômio 3

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH

Sair da comparação
NTLH Nova Tradução na Linguagem de Hoje 2000
1 Lẹ́yìn èyí ní a yípadà tí a sì kọrí sí ọ̀nà tí ó lọ sí Baṣani, Ogu ọba Baṣani àti gbogbo jagunjagun rẹ̀ ṣígun wá pàdé wa ní Edrei.
1 Moisés continuou: — Depois fomos na direção do norte até a região de Basã. E Ogue, rei de Basã, saiu com o seu exército para lutar contra nós na cidade de Edrei.
2 Olúwa sọ fún mi pé, “Má ṣe bẹ̀rù rẹ̀, nítorí tí mó tí fi òun lé ọ lọ́wọ́, àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, àti ilẹ̀ rẹ̀. Kí ìwọ kí ó ṣe sí i gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti ṣe sí Sihoni ọba Amori ẹni tí ó ń jẹ ọba ní Heṣboni.”
2 Mas o Senhor Deus me disse: “Não tenha medo, pois eu farei com que você derrote Ogue e o seu exército, e você vai tomar posse da terra dele. Você será vitorioso, como foi contra Seom, o rei dos amorreus, que morava em Hesbom.”
3 Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa Ọlọ́run wa fi Ogu ọba Baṣani àti àwọn jagunjagun rẹ̀ lé wa lọ́wọ́. A kọlù wọ́n títí kò fi ku ẹnìkan fún un láàyè.
3 — O Senhor , nosso Deus, fez com que derrotássemos Ogue e todo o seu exército, e nós matamos todos, sem deixar ninguém vivo.
4 Ní ìgbà náà ní a gba gbogbo àwọn ìlú rẹ̀. Kò sí ọ̀kankan tí a kò gbà nínú àwọn ọgọta ìlú tí wọ́n ní, gbogbo agbègbè Argobu, lábẹ́ ìjọba Ogu ní Baṣani.
4 Também conquistamos todas as cidades de Argobe, a terra da região de Basã que pertencia a Ogue. Eram ao todo sessenta cidades,
5 Gbogbo ìlú wọ̀nyí ní a mọ odi gíga yíká pẹ̀lú àwọn ìlẹ̀kùn àti irin. Ọ̀pọ̀ àwọn ìlú kéékèèké tí a kò mọ odi yíká sì tún wà pẹ̀lú.
5 todas elas protegidas por muralhas altas e com portões reforçados. Conquistamos também muitas cidades que não tinham muralhas.
6 Gbogbo wọn ni a parun pátápátá gẹ́gẹ́ bí á ti ṣe sí Sihoni ọba Heṣboni, tí a pa gbogbo ìlú wọn run pátápátá: tọkùnrin tobìnrin àti àwọn ọmọ wọn.
6 Nós as destruímos completamente e matamos todos os homens, mulheres e crianças, como tínhamos feito na guerra contra Seom, rei de Hesbom.
7 Ṣùgbọ́n a kó gbogbo ohun ọ̀sìn àti ìkógun àwọn ìlú wọn, fún ara wa.
7 Mas ficamos com o gado e com os objetos de valor que encontramos nas cidades.
8 Ní ìgbà náà ni a ti gba ilẹ̀ tí ó wà ní Jordani láti odò Arnoni, títí dé orí òkè Hermoni lọ́wọ́ àwọn ọba Amori méjèèjì wọ̀nyí.
8 — Foi assim que conquistamos naquele tempo as terras daqueles dois reis amorreus na região a leste do rio Jordão, desde o rio Arnom até o monte Hermom.
9 (Àwọn ará Sidoni ń pe Hermoni ní Sirioni. Àwọn Amori sì ń pè é ní Seniri).
9 (Os sidônios chamam o monte Hermom de Siriom, e os amorreus o chamam de Senir.)
10 Gbogbo àwọn ìlú tí ó wà ní orí òkè olórí títẹ́ náà ni a gbà àti gbogbo Gileadi, àti gbogbo Baṣani, títí dé Saleka, àti Edrei, ìlú àwọn ọba Ogu ní ilẹ̀ Baṣani.
10 Conquistamos todas as cidades do planalto e toda a região de Gileade e de Basã, até as cidades de Salca e Edrei, na parte leste de Basã.
11 (Ogu tí í ṣe ọba Baṣani nìkan ni ó ṣẹ́kù nínú àwọn ará Refaimu. Ibùsùn rẹ̀ ni a fi irin ṣe, ó sì gùn ju ẹsẹ̀ bàtà mẹ́tàlá lọ ní gígùn àti ẹsẹ̀ bàtà mẹ́fà ní ìbú. Èyí sì wà ní Rabba ti àwọn Ammoni.)
11 (Ogue, rei de Basã, foi o último rei da raça de gigantes chamados refains . A sua cama, feita de ferro, media quatro metros de comprimento por um metro e oitenta de largura, de acordo com a medida usada naquele tempo. A cama ainda está na cidade de Rabá, no país de Amom.)
12 Nínú àwọn ilẹ̀ tí a gbà ní ìgbà náà, mo fún àwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi, ní ilẹ̀ tí ó wà ní àríwá Aroeri níbi odò Arnoni, pọ̀ mọ́ ìdajì ilẹ̀ òkè Gileadi pẹ̀lú gbogbo ìlú wọn.
12 Moisés continuou: — Depois que tomamos posse da região a leste do rio Jordão, dei às
13 Gbogbo ìyókù Gileadi àti gbogbo Baṣani, ní ilẹ̀ ọba Ogu ni mo fún ìdajì ẹ̀yà Manase. (Gbogbo agbègbè Argobu ni Baṣani tí a mọ̀ sí ilẹ̀ àwọn ará Refaimu.
13 E para uma metade da tribo de Manassés dei o resto de Gileade e toda a região de Basã, onde Ogue havia sido rei, isto é, a terra de Argobe. (Toda a região de Basã era conhecida como a terra dos
14 Jairi ọ̀kan nínú àwọn ìran Manase gba gbogbo agbègbè Argobu títí dé ààlà àwọn ará Geṣuri àti àwọn ará Maakati; a sọ ibẹ̀ ní orúkọ rẹ̀ torí èyí ni Baṣani fi ń jẹ́ Hafoti-Jairi títí di òní.)
14 Jair, que era descendente de Manassés, conquistou toda a região de Argobe, isto é, Basã, até a fronteira com Gesur e Maacá. Ele pôs o seu nome nas cidades dali, e até hoje elas são conhecidas como as cidades de Jair.)
15 Mo sì fi Gileadi fún Makiri,
15 — Eu dei a região de Gileade ao grupo de famílias de Maquir.
16 ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Reubeni àti ọmọ Gadi ni mo fún ní ilẹ̀ láti Gileadi lọ dé odò Arnoni (àárín odò náà sì jẹ́ ààlà) títí ó fi dé odò Jabbok. Èyí tí i ṣe ààlà àwọn ará Ammoni.
16 E para as tribos de Rúben e de Gade dei o território que vai desde a região de Gileade na direção do sul até o vale do rio Arnom; a divisa fica no meio do vale. Para o norte as suas terras vão até o rio Jaboque, que fica na fronteira com a terra dos amonitas.
17 Pẹ̀tẹ́lẹ̀ Arabah pẹ̀lú, àti Jordani gẹ́gẹ́ bí òpin ilẹ̀ rẹ̀, láti Kinnereti lọ títí dé Òkun pẹ̀tẹ́lẹ̀ Arabah, àní Òkun Iyọ̀, ní ìsàlẹ̀ àwọn orísun Pisga ní ìhà ìlà-oòrùn.
17 Para o oeste o seu território vai até o rio Jordão, desde o lago da Galileia, no Norte, até o mar Morto, no Sul, e até o pé do monte Pisga, no Leste.
18 Mo pàṣẹ fún un yín ní ìgbà náà pé, “Olúwa Ọlọ́run yín ti fi ilẹ̀ yìí fún un yín láti ní i. Ṣùgbọ́n, gbogbo àwọn ọkùnrin yín tí ó lera tí wọ́n sì ti dira ogun, gbọdọ̀ kọjá síwájú àwọn arákùnrin yín: ará Israẹli.
18 — Foi nessa ocasião que dei às tribos de Rúben e de Gade e à metade leste da tribo de Manassés a seguinte ordem: “O Senhor , nosso Deus, lhes deu essas terras a leste do rio Jordão, e vocês tomaram posse delas. Agora, que os homens peguem as suas armas e atravessem o rio Jordão na frente dos seus patrícios para ajudá-los a tomar posse das terras deles.
19 Àwọn ẹ̀yà a yín, àwọn ọmọ yín àti àwọn ohun ọ̀sìn in yín (mo mọ̀ pé ẹ ti ní ohun ọ̀sìn púpọ̀) lè dúró ní àwọn ìlú tí mo fi fún un yín,
19 Mas as mulheres, as crianças e o gado — e eu sei que vocês têm muito gado — ficarão aqui nas cidades que já dei a vocês.
20 títí di ìgbà tí Olúwa yóò fún àwọn arákùnrin yín ní ìsinmi bí ó ti fún un yín, àti ìgbà tí àwọn náà yóò fi gba ilẹ̀ náà tí Olúwa Ọlọ́run yín ti fún wọn ní ìhà kejì Jordani. Nígbà náà ni ọ̀kọ̀ọ̀kan yín tó lè padà lọ sí ìní rẹ̀ tí mo fún un.”
20 Ajudem os seus patrícios até que eles acabem de tomar posse das terras que o Senhor , nosso Deus, está dando a eles a oeste do rio Jordão e até que estejam morando ali em paz, como vocês estão nas suas terras. Aí vocês poderão voltar e morar na terra que eu lhes dei aqui, a leste do Jordão.”
21 Nígbà náà ni mo pàṣẹ fún Joṣua pé, “Ìwọ tí fi ojú rẹ rí ohun gbogbo tí Olúwa Ọlọ́run rẹ tí ṣe sí àwọn ọba méjèèjì wọ̀nyí. Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa yóò ṣe sí àwọn ilẹ̀ ọba tí ẹ̀yin n lọ.
21 — Também falei com Josué e disse: “Você viu o que o Senhor Deus fez com aqueles dois reis, Seom e Ogue. Pois é isso mesmo o que ele fará com os reis de todas as terras que vocês vão invadir.
22 Ẹ má ṣe bẹ̀rù wọn, Olúwa Ọlọ́run yín tìkára rẹ̀ ni yóò jà fún un yín.”
22 Não tenham medo deles, pois o Senhor , seu Deus, combaterá por vocês.”
23 Nígbà náà ni mo bẹ Olúwa wí pé,
23 — Nessa ocasião eu também orei a Deus, o Senhor , dizendo:
24 “Olúwa Olódùmarè, ìwọ tí bẹ̀rẹ̀ sí fi títóbi rẹ àti ọwọ́ agbára rẹ han ìránṣẹ́ rẹ. Ọlọ́run wo ló tó bẹ́ẹ̀ láyé àti lọ́run tí ó lè ṣe àwọn iṣẹ́ agbára ńlá tí o ti ṣe?
24 “Ó Senhor , meu Deus, eu sei que começaste a mostrar a tua grandeza e o teu poder a mim, teu servo . Pois não existe outro deus no céu ou na terra que possa fazer coisas tão grandes e maravilhosas como tu tens feito!
25 Jẹ́ kí n kọjá lọ wo ilẹ̀ rere ti ìkọjá Jordani, ilẹ̀ òkè dídára nì àti Lebanoni.”
25 Peço-te, pois, que me deixes atravessar o rio Jordão e ver a boa terra que fica no outro lado, a bela região montanhosa e os montes Líbanos.”
26 Ṣùgbọ́n torí i tiyín, Olúwa Ọlọ́run bínú sí mi kò sì gbọ́ tèmi. Olúwa sọ wí pé, “Ó tó gẹ́ẹ́, ìwọ kò gbọdọ̀ sọ ohunkóhun lórí ọ̀rọ̀ yìí sí mi mọ́.
26 — Mas por causa de vocês o Senhor estava irado comigo e não atendeu o meu pedido. Pelo contrário, ele disse: “Chega! Não fale mais nisso!
27 Gòkè lọ sí orí òkè Pisga, sì wò yíká ìwọ̀-oòrùn, ìlà-oòrùn, àríwá àti gúúsù. Fi ojú ara rẹ wo ilẹ̀ náà níwọ̀n bí ìwọ kò tí ní kọjá Jordani yìí.
27 Suba o monte Pisga e lá de cima olhe para o norte e para o sul, para o leste e para o oeste. Olhe bem toda a terra, pois você não vai atravessar o rio Jordão.
28 Ṣùgbọ́n yan Joṣua, kí o sì gbà á níyànjú, mú un lọ́kàn le, torí pé òun ni yóò síwájú àwọn ènìyàn wọ̀nyí kọjá, yóò sì jẹ́ kí wọn jogún ilẹ̀ náà tí ìwọ yóò rí.”
28 Dê conselhos a Josué; anime-o e encoraje-o, pois ele vai comandar o povo de Israel na conquista desta terra que você está vendo.”
29 Báyìí ni a dúró ní àfonífojì ní ẹ̀bá Beti-Peori.
29 — Então paramos no vale que fica perto da cidade de Bete-Peor.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Deuteronômio 3, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.