Atos 7

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Nígbà náà ni olórí àlùfáà wí pé, “Òtítọ́ ha ni àwọn ẹ̀sùn tí wọ́ fi kàn ọ́ bí?”
1 Imaibo Firis Gagamin Stephen ibatiy, “Tur iti i anababatun o isa teo?”
2 Ní ìdáhùn sí èyí ó wí pé, “Ẹ̀yin arákùnrin àti ẹ̀yin baba, ẹ fetísílẹ̀ sí mi! Ọlọ́run ògo fi ara hàn fún Abrahamu baba wa, nígbà tí ó wà ni Mesopotamia, kí ó to ṣe àtìpó ni Harani.
2 Stephen iya’afut eo, “Taitu tuwai’inah naatu tamai’inah anao kwananowar! Ata agir Abraham ufibo na Haram imaim ma, baise wan Mesopotamia ma’am ana veya’amaim Marakaw ana God isan irerereb eo. Stephen Ebibinan|alt="Stephen preaching" src="cn01914B.tif" size="col" loc="Act 7.2" copy="©1978 David C. Cook Publishing Co." ref="7.2"
3 Ọlọ́run wí fún un pé, ‘Jáde kúrò ní orílẹ̀-èdè rẹ àti kúrò lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ, lọ sí ilẹ̀ kan tí èmi yóò fihàn ọ́.’
3 ‘A tafaram naatu taituwa inihamiyih inan tafaram ayu ana bi’obaiyi imaim inama.’
4 “Nígbà náà ni ó jáde kúrò ní ilẹ̀ àwọn ará Kaldea, ó sì ṣe àtìpó ni Harani. Lẹ́yìn ìgbà tí baba rẹ̀ sì kú, Ọlọ́run mú un sípò padà wá sí ilẹ̀ yìí, níbi tí ẹ̀yin ń gbé báyìí.
4 Imih Kaldia tafaram ihamiy naatu na Haram imaim ma. Tamah momorob ufunamaim God nawiy na me tafaram iti bitin boun kwa iti kwama’am.
5 Kò sí fún un ni ìní kan, ànító bi ìwọ̀n ààyè ẹsẹ̀ kan. Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ṣe ìlérí fún pé, òun yóò fi ilẹ̀ ìní náà fún un àti fún àwọn irú-ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀, nígbà tí kò tí ì ní ọmọ.
5 God men abisa ta Abraham nowanamih itin naatu men kafa’imo me kikimin eafuw nowanamih itin. Baise God eomatan tafaram tutufin etei boro nowanamih nab naatu wawawan uf hinatutufuw boro hinab. Nati ana veya’amaim Abraham i aurin kek en ma’am God eomatan.
6 Ọlọ́run sì sọ báyìí pé, ‘Irú-ọmọ rẹ yóò ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àjèjì; wọn ó sì sọ wọn di ẹrú, wọn ó sì pọ́n wọn lójú fún irinwó (400) ọdún.
6 Naatu God iti na’atube eo, ‘O wawaw i boro nah toumanih hai tafaramamaim hinama, nati’imaim boro nah toumanih hai fair babanamaim hinama bowabow fokarin maiyow hinabow, hinarouw hini’a’afiyih kwamur etei 400 na’atube nasawar.’
7 Ọlọ́run wí pé, Orílẹ̀-èdè náà tí wọn yóò máa sìn, ni èmi ó dá lẹ́jọ́; lẹ́yìn náà ni wọn ó sì jáde kúrò, wọn ó sì wá sìn mí níhìn-ín yìí.’
7 Baise God iuwih eo, ‘Ayu nati tafaram hinabuwi babahimaim kwanama kwanabowabow boro baimakiy anitih. Nati ufunamaim boro tafaram kwanihamiy kwanatit efan iti’imaim ayu kwanakwafiru.
8 Ó sì fún Abrahamu ni májẹ̀mú ìkọlà. Abrahamu bí Isaaki, ó kọ ọ́ ní ilà ni ọjọ́ kẹjọ tí ó bí i. Isaaki sí bí Jakọbu, Jakọbu sì bí àwọn baba ńlá méjìlá.
8 Imaibo God ar afu’afuw ana obaibasit Abraham itin ina’inanen na’atube kaif. Imih Abraham natun Isaac tufuw fur ta’imon sasawar ufunamaim ana ar kanabin e’afuw. Nati ufunamaim Isaac natun Jacob ana ar kanabin e’afuw naatu Jacob natunatun 12 it uwatanah wabih gagamin auman hai ar kanabih e’afuw.
9 “Àwọn baba ńlá sí ṣe ìlara Josẹfu, wọ́n sì tà á sí Ejibiti; ṣùgbọ́n Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀,
9 Baise uwatanah wabih gagamin Joseph isan hibobowen akir wairafin na’atube hitih hitubun hibai hin Egypt imaim ma. Baise God i mar etei biyanamaim ma’am.
10 ó sì yọ ọ́ kúrò nínú ìpọ́njú rẹ̀ gbogbo. Ó sì fún Josẹfu ní ọgbọ́n, ó sì mú kí ó rí ojúrere Farao ọba Ejibiti; òun sì fi jẹ baálẹ̀ Ejibiti àti gbogbo ilé rẹ̀.
10 Naatu ana yababan ta ta wanawanamaim bibais. Veya ta Joseph Egypt hai aiwob nanamaim titit ana veya aiwob orot Joseph i’itin yan bai naatu ana kakaf isan ma, anayabin God ukwar rerekab Joseph itin. Imih aiwob orot Joseph bai ana gawanamih yai, naatu aiwob ana bar gagamin wanawanan auman kaifin isan ana fair itin.” Joseph Egypt sabuw ebobonawiyih|alt="Joseph as ruler" src="cn01917b.tif" size="col" loc="Act 7.10" copy="©1978 David C. Cook Publishing Co." ref="7.10"
11 “Ìyàn kan sì mú ni gbogbo ilẹ̀ Ejibiti àti ni Kenaani, àti ìpọ́njú ńlá, àwọn baba wa kò sì rí oúnjẹ.
11 “Nati ana veya’amaim baimar kakafin na, Egypt naatu Canaan tafaram wanawanan yababan gagamin na’in matar, naatu it uwatanah bayumih hi’akir.
12 Ṣùgbọ́n nígbà tí Jakọbu gbọ́ pé alikama ń bẹ ni Ejibiti, ó rán àwọn baba wa lọ lẹ́ẹ̀kínní.
12 Egyptamaim bay ma’am ana tur Jacob nonowar ana veya uwatanah hai nanawan wantoro’ot imaim hin.
13 Nígbà kejì Josẹfu fi ara rẹ̀ hàn fún àwọn arákùnrin rẹ̀, a sì tún fi wọ́n hàn fún Farao.
13 Hai nanawan bairou’abin ana veya Joseph taiyuwin botait irerereb tuwahinah hai tur eowen, naatu Pharaoh nati’imaim Joseph ana nibur isah so’ob.
14 Lẹ́yìn èyí, Josẹfu ránṣẹ́ pe Jakọbu baba rẹ̀, àti àwọn ìbátan rẹ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ, gbogbo wọ́n sì tó àrùndínlọ́gọ́rin ọkàn.
14 Nati ufunamaim Joseph tamah Jacob isan, naatu tamah ana nibur isah tur iyafar, nah etei 75 na’atube.
15 Nígbà náà ni Jakọbu sọ̀kalẹ̀ lọ sí Ejibiti, ní ibi tí òun àti àwọn baba wa kú sí.
15 Imaibo Jacob rena Egypt tit, nati’imaim i natunatun bairi himorob, it uwatanah.
16 A sì gbé òkú wọn padà wá sí Ṣekemu, a sì tẹ́ wọn sínú ibojì ti Abrahamu rà ni ọwọ́ àwọn ọmọ Amori ní Ṣekemu ní iye owó wúrà kan.
16 Naatu biyah i hibow himatabir maiye tafaram wabin Shekem rahamaim hiya, nati me i Abraham orot Hamor natunatun biyahine tubun.
17 “Nígbà tí àkókò tí Ọlọ́run yóò mú ìlérí tí ó ṣe fún Abrahamu ṣẹ kù sí dẹ̀dẹ̀, àwọn ènìyàn wa ń gbèrú si gidigidi ní iye ní ilẹ̀ Ejibiti.
17 “God ana omatanen Abraham eo’omatan na baiturobe isan ana veya na kabom, naatu ata sabuw Egypt hima’am busuruf ra’at tafaram awan karatan.
18 Ṣùgbọ́n ọba tuntun mìíràn tí kò mọ Josẹfu jẹ ní ilẹ̀ Ejibiti.
18 Imaibo aiwob orot ta Joseph men susu’ub i busuruf Egypt isan i’aiwob.
19 Òun náà ni ó ṣe àrékérekè sí àwọn ìbátan wa. Wọn sì hùwà búburú sí àwọn baba wa, tó bẹ́ẹ̀ tí wọ́n fi já àwọn ọmọ ọwọ́ wọn kúrò lọ́wọ́ wọn nítorí kí wọn má ṣe yè.
19 Ata a’agir ifufuwih, biyababan kakafin anababatun itih, eokikinih hai kek sosof hisrouwen hi’in himorob.
20 “Ní àkókò náà ni a bí Mose ọmọ tí ó se iyebíye, tí wọn sí bọ́ lóṣù mẹ́ta ni ilé baba rẹ̀.
20 “Nati ana veya’amaim Moses tufuw, kek ana itinin gewasin maiyow. Baremaim hinah tamah hibunwa’ir ma sumar etei tounu na’atube sawar.
21 Nígbà tí wọn sí gbe é sọnù, ọmọbìnrin Farao gbé e, ó sì tọ ọ́ dàgbà gẹ́gẹ́ bí ọmọ ara rẹ̀.
21 Imaibo barene hibotait titit ana veya, Pharaoh natun babitai natunamih bai ituw ra’at yen orot matar.
22 A sì kọ́ Mose ni gbogbo ọgbọ́n ara Ejibiti, ó sì pọ̀ ni ọ̀rọ̀ àti ní ìṣe.
22 Egypt ana ukwar rerekab etei Moses hi’obaiy so’ob, naatu ana tur ana sinafumaim eo sisinaf etei i fairih.
23 “Nígbà tí Mose di ọmọ ogójì ọdún, ó sọ sí i lọ́kàn láti lọ bẹ àwọn ọmọ Israẹli ará rẹ̀ wò.
23 “Moses ana kwamur etei 40 na’atube baib ana maramaim ana not bogaigiwas tit ana sabuw Israel inananawanih.
24 Nígbà tí ó sì rí ọ̀kan nínú wọ́n tí ará Ejibiti kan ń jẹ́ ní ìyà, ó gbèjà rẹ̀, ó gbẹ̀san ẹni tí wọ́n jẹ ní ìyà nípa lílu ará Ejibiti náà pa.
24 Tit inan Egypt orot ta Israel orot boborabirab itin, basit na ibais wasfafar naatu anasa bow Egypt orot rab morob.
25 Mose rò bí àwọn ará òun mọ̀ pé Ọlọ́run yóò ti ọwọ́ òun gbà wọn; ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀.
25 Moses not eo, ‘God ana baibais ayu wanawana’umaim esisinaf au sabuw boro hina’itin hinaso’ob, baise men hi’itinimih.’
26 Ní ọjọ́ kejì Mose yọ sí àwọn ọmọ Israẹli méjì bí wọ́n ti ń jà. Òun si fẹ́ parí ìjà fún wọn. Ó wí pé, ‘Ènìyàn mi, ará ni ẹ̀yin; èéṣe tí ẹ̀yin fi ń ṣe ohun tí kò tọ́ sí ara yín?’
26 Marto Israel orot rou’ab hairi hibiyow itih, basit na fafar naatu iuwih, ‘Kwa airi i ain uf, aisim taiyuw kwabiyow?’
27 “Ṣùgbọ́n ẹni tí ó fínràn sí ẹnìkejì rẹ̀ ti Mose sí ẹ̀gbẹ́ kan, ó wí pé, ‘Ta ni ó fi ọ́ jẹ olórí àti onídàájọ́ lórí wa?
27 Baise orot ta biwa’an kakafene Moses rukouw eo, ‘O aki bainabatani naatu baibabatiyi isan yait rubini?’
28 Ṣé ìwọ fẹ́ pa mí bí o ti pa ará Ejibiti lánàá?’
28 ‘O kukokok ayu ina’asbunu fai Egypt orot ia’asabun na’atube?’
29 Mose sì sá nítorí ọ̀rọ̀ yìí, ó sì wa ṣe àtìpó ni ilẹ̀ Midiani, níbi tí ó gbé bí ọmọ méjì.
29 Moses iti tur nonowar ana veya Egypt ihamiy bihir in tafaram wabin Midian imaim ma, nati’imaim touman orot na’atube ma’am natunatun orot rou’ab hitufuw.
30 “Nígbà tí ogójì ọdún sì pé, angẹli Olúwa fi ara han Mose ní ijù, ní òkè Sinai, nínú ọ̀wọ́-iná nínú igbó.
30 Kwamur 40 sasawar ufunamaim oyaw Sinai sisibinamaim arar yan tounamatar Moses isan irerereb wairaf na’atube wa’ab wanawanan to’ab.
31 Nígbà tí Mose sì rí i, ẹnu yà á sí ìran náà; nígbà tí ó sì súnmọ́ ọn láti wò ó fín, ohùn Olúwa kọ sí i,
31 Moses iti wairaf to’ab i’itin ana veya ana kasiy ra’at, naatu itinbunai isan na biyubin auman Regah fanan nowar;
32 wí pé ‘Èmi ni Ọlọ́run àwọn baba rẹ, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki, àti Ọlọ́run Jakọbu,’ Mose sì wárìrì pẹ̀lú ìbẹ̀rù, kò sì dáṣà láti wò ó mọ́.
32 ‘Ayu i o uwatanah hai God, Abraham ana God, Isaac, naatu Jacob.’ Moses yan wanawanan birubir fafar an uman hioror naatu men karam boro tanuw ta’itin.
33 “Olúwa sì wí fún un pé, ‘Bọ́ bàtà rẹ kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ, nítorí ibi tí ìwọ dúró sí i nì ilẹ̀ mímọ́ ni.
33 Imaibo Regah eo, ‘A ana sumasum kubosair anayabin iti kamar i kakafiyin yan kubatabat.
34 Ní rí rí, mo ti rí ìpọ́njú àwọn ènìyàn mi tí ń bẹ ni Ejibiti, mo sì ti gbọ́ ìkérora wọn, mo sì sọ̀kalẹ̀ wá láti gbà wọ́n. Wá nísinsin yìí, Èmi ó sì rán ọ lọ sí ilẹ̀ Ejibiti.’
34 Ayu au sabuw Egypt imaim bai’akir kakafin maiyow hibaib aitih, naatu hitef hirererey anowar, imih rufamih botaitih isan are ana. O kuna aiyafari kumatabir maiye au Egypt.’
35 “Mose náà yìí tí wọ́n kọ̀, wí pé, ‘Ta ni ó fi jẹ olórí àti onídàájọ́?’ Òun náà ni Ọlọ́run rán lọ láti ọwọ́ angẹli, tí ó farahàn án ní pápá, láti ṣe olórí àti olùdáǹdè.
35 “Moses i orot ta’imon Israel sabuw hikwahir hiu, ‘O yait rubini aki bainabatani naatu baibatiyi isan?’ Nati orot ta’imon sabuw bainabatanih naatu rufamih botaitih isan God taiyuwin ana tounamatar iyafar na wa’ab toto’abamaim irerereb Moses fair itin.
36 Òun ni ó mú wọn jáde, lẹ́yìn ìgbà tí ó ṣe iṣẹ́ ìyanu àti iṣẹ́ àmì ní ilẹ̀ Ejibiti, àti ni Òkun pupa, àti ni aginjù ní ogójì ọdún.
36 Sabuw nawiyih Egypt hihamiy hitit, naatu ina’inan men hi’i’itah efa’efanin Egyptamaim, Red Sea imaim, naatu kwamur 40 arar yanamaim iwa’an hi’itah.
37 “Èyí ni Mose náà ti ó wí fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Ọlọ́run yóò gbé wòlíì kan bí èmi dìde nínú àwọn ènìyàn yín.’
37 “Iti orot Moses i boun Israel sabuw hai tur eowen, ‘God boro dinab orot kwa wanawananamaim a orot ta niyafar nan, ayu biyafaru na’atube.’
38 Èyí náà ni ẹni tí ó wà nínú ìjọ ní ijù pẹ̀lú angẹli náà tí ó bá a sọ̀rọ̀ ní orí òkè Sinai, àti pẹ̀lú àwọn baba wa; ẹni ti ó gba ọ̀rọ̀ ìyè láti fi fún wa.
38 Iti orot Moses Israel sabuw bairi kou’ay hibai arar yanamaim hibat naatu ata a’agir bairi Sinai oyawemaim tounamatar tur yawasin bai re itin naatu ya’abun it isat rena.
39 “Ṣùgbọ́n àwọn baba wa kò fẹ́ gbọ́ tirẹ̀. Dípò bẹ́ẹ̀, wọ́n kọ̀ ọ́ sílẹ̀, àti pé nínú ọkàn wọn, wọn fẹ́ yípadà lọ sí ilẹ̀ Ejibiti.
39 Baise it ata a’agir fanan men hibosiyasiyar, naatu fanan hikwahir hikokok i mi’itube hitamatabir maiye hitan Egypt hitatit.
40 Wọ́n wí fún Aaroni pé, ‘Dá òrìṣà fún wa tí yóò máa tọ́nà ṣáájú wa; nítorí bí ó ṣe ti Mose yìí tí ó mú wa jáde wá láti ilẹ̀ Ejibiti, a kò mọ̀ ohun tí ó ṣe é.’
40 Imih Aaron hiu, ‘Aki akokok god ta kusinaf au nai i’iyon ebonawiyi. Moses Egyptane nawiyi atitit men aso’ob abisa isan matar.’
41 Wọ́n sì yá ère ẹgbọrọ màlúù ni ọjọ́ wọ̀nyí. Wọ́n sì rú ẹbọ sí ère náà, wọ́n sì ń yọ̀ nínú ohun tí wọ́n fi ọwọ́ ara wọn ṣe.
41 Nati ana veya’amaim aibat ta cow natun ana yumatabe hibu’ur. Naatu sibor hibow hina sawar i umahimaim hisinaf mamatar ana sibor hiyai naatu ana hiyuw hibow hiyasisir.
42 Ọlọ́run sì padà, ó fi wọn sílẹ̀ láti máa sin ogun ọ̀run: òòrùn, òṣùpá àti ìràwọ̀. Èyí wà ní ìbámu pẹ̀lú bí a ti kọ ọ́ nínú ìwé àwọn wòlíì pé:
42 Baise God mafutih, naatu mar ana sawar kwafirih isan ibasit. Dinab orot hai Bukamaim hikikirum na iturobe,
43 Ẹ̀yin sì tẹ́wọ́gbà àgọ́ Moleki,
43 Kwa i god Moloch ana sis kwa’abar kwareremor,
44 “Àwọn baba wa ní àgọ́ ẹ̀rí pẹ̀lú wọn ní ijù. Èyí tí a ṣe gẹ́gẹ́ bí Ọlọ́run tí ó ba Mose sọ̀rọ̀ pé kí ó ṣe é, gẹ́gẹ́ bí àpẹẹrẹ tí ó ti rí.
44 “Ata a’agir God ana sis arar yanamaim hiyai hima’am i God ana itinin nati’imaim bairi hima’am. Nati sis i God mi’itube Moses iu bi’obaiy na’atube naatu God yayakitifuw na’atube hiwowab.
45 Ti àwọn baba wa tí ó tẹ̀lé wọn sí mú bá Joṣua wá sí ilẹ̀ ìní àwọn aláìkọlà, tí Ọlọ́run lè jáde kúrò níwájú àwọn baba wa, títí dí àkókò Dafidi.
45 Nati ufunamaim, ata a’agir sis tamahinah biyahine nan hibai hi’abar Joshua babanamaim bonawiyih bairi hirun sabuw afa hai tafaram God nunih hititit i hai tafaram hibai. Naatu nati sis i ma’am David ana veya’amaim tit.
46 Ẹni tí ó rí ojúrere níwájú Ọlọ́run, tí ó sì tọrọ láti rí ibùgbé fún Ọlọ́run Jakọbu.
46 David ana baibais gagamin na’in God biyanane bai, imih ifefeyan bar tawowab. Jacob ana God isan
47 Ṣùgbọ́n Solomoni ni ó kọ́ ilé fún un.
47 baise iti bar i Solomon wowab.
48 “Ṣùgbọ́n Ọ̀gá-ògo kì í gbé ilé ti a fi ọwọ́ kọ́, gẹ́gẹ́ bí wòlíì ti wí pé:
48 “Baise Auyomtoro’ot ana God i men orot bar tewowowabimaim ema’ama’amih, dinab orot eo kikirum na’atube.
49 “ ‘Ọ̀run ni ìtẹ́ mi,
49 ‘Mar i ayu au urama’ama,
50 Ọwọ́ mi kò ha ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí.’
50 Sawar iti kwanotanot men ayu asinaf himatar?’
51 “Ẹ̀yin ọlọ́rùn líle àti aláìkọlà àyà àti etí! Bí àwọn baba yín gẹ́lẹ́ ni ẹ̀yin rí. Nígbà gbogbo ni ẹ̀yin máa ń dènà Ẹ̀mí Mímọ́!
51 “Kwa i dogor fokarih naatu dogor wanawanan gugumin naatu tain gugurih God ana tur men kwanonowar! Kwa i a’a’agir ah kwabat, mar etei Anun Kakafiyin kwarurukouw!
52 Ǹjẹ́ ọ̀kan tilẹ̀ wà nínú àwọn wòlíì tí àwọn baba yín kò ṣe inúnibíni sí? Wọn sì ti pa àwọn ti ó ti ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa wíwá Ẹni Olódodo náà. Nísinsin yìí ẹ̀yin ti dalẹ̀ rẹ̀ ẹ̀yin sí ti pa.
52 Kwa a’agir dinab orot marasika hima’am etei hirouw hi’a’akirih, nati dinab oro’orot i marasika iti orot gewasin nan isan hikurereb. Baise kwa uwatanah hirouw himorob, naatu boun kwa iti orot gewasin nan baban kwao kwarab morob.
53 Ẹ̀yin tí ó gba òfin, gẹ́gẹ́ bí àwọn angẹli ti fi fún ni, tí ẹ kò sì pa á mọ́.”
53 Kwa i God ana ofafar tounamatar hiyafar re’er kwabai, baise men kwabobosiyasiyar!”
54 Nígbà tí wọn sì gbọ́ nǹkan wọ̀nyí ọkàn wọn gbọgbẹ́ dé inú, wọn sì payínkeke sí i.
54 Kaniser hima Stephen eo hinonowar yah so’ar gagamat bufutih hikarmusiyan himisir
55 Ṣùgbọ́n Stefanu, ẹni tí ó kún fún Ẹ̀mí Mímọ́, ó tẹjúmọ́ ọ̀run, ó sì rí ògo Ọlọ́run, àti Jesu dúró ní ọwọ́ ọ̀tún Ọlọ́run.
55 Baise Stephen God Anun Kakafiyin biyan etei karatan batabat au mar nuwra’at God ana marakaw itin naatu Jesu sisibin asukwafune batabat itin.
56 Ó sì wí pé, “Wò ó, mo rí ọ̀run ṣí sílẹ̀, Ọmọ Ènìyàn sì dúró ní ọwọ́ ọ̀tún Ọlọ́run.”
56 Basit eo, “Kwanuw ra’at! Ayu mar ana etawan botawiy Orot Natun God ana asukwafune bat ai’itin!”
57 Nígbà náà ni wọn kígbe ní ohùn rara, wọn sí di etí wọ́n, gbogbo wọn sì sáré sí i, wọ́n sì rọ́ lù ú,
57 Fanah aumetawat hiwow tainih higibud, imaibo etei au ta’imon hinunuw hibai
58 wọ́n sì wọ́ ọ sẹ́yìn òde ìlú, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sísọ ọ́ ní òkúta; àwọn ẹlẹ́rìí sì fi aṣọ wọn lélẹ̀ lẹ́sẹ̀ ọmọkùnrin kan tí a ń pè ní Saulu.
58 hitain hitit bar merar gagamin ufunane hitaiy re kabayamaim hirab, orot iyab baifuwenamaim sif hirurubon, hai faifuw nati orot boubun wabin Saul anamaim hiya.
59 Bí wọ́n ti ń sọ Stefanu ní òkúta, ó sì ké pe Olúwa wí pé, “Jesu Olúwa, gba ẹ̀mí mi.”
59 Kabayamaim hibat hirabirab auman Stephen Regah isan ifefeyan eo “Regah Jesu ayubu kubai!”
60 Nígbà náà ni ó wólẹ̀ lórí eékún rẹ̀, ó kígbe sókè pé, “Olúwa, má ṣe ka ẹ̀ṣẹ̀ yìí sí wọn ní ọrùn.” Nígbà ti ó sì wí èyí tán, ó sùn lọ.
60 Sun yowen fanan aumetawat erererey auman i wow eo, “Regah abisa ayu isou tisisinaf hai

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Atos 7, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.