Apocalipse 6
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Èmi sì rí i nígbà tí Ọ̀dọ́-àgùntàn náà ṣí ọkàn nínú èdìdì wọ̀nyí, mo sì gbọ́ ọ̀kan nínú àwọn ẹ̀dá alààyè mẹ́rin náà ń wí bí sísán àrá pé, “Wá, wò ó!”
1 Imaibo buk etei seven hikwahen hi’inu’in Lamb ta bai bobotawiy aitin, naatu sawar yawasih ma’anih kwafe’en, ta fanan gunum na’atube e’af, “Kuna!”
2 Mo sì wò ó, kíyèsi i, ẹṣin funfun kan: ẹni tí ó sì jókòó lórí i rẹ̀ ní ọfà kan; a sì fi adé kan fún un: ó sì jáde lọ láti ìṣẹ́gun dé ìṣẹ́gun.
2 Ayu anuwanuw horse biyan kwes, tafanamaim orot uman few auman ma’am aitin. Naatu nati orot ukwarinamaim i kowas gold hiyara’ah sabuw rouw baigegsairihimih tit.
3 Nígbà tí ó sì ṣí èdìdì kejì, mo gbọ́ ohùn ẹ̀dá alààyè wí pé, “Wá, wò ó!”
3 Buk bairou’abin hikwah inu’in Lamb bai kwibikwib ana veya, ayu sawar yawasih ma’anih bairou’abin e’afa’af fanan anowar eo, “Kuna!”
4 Ẹṣin mìíràn tí ó pupa sì jáde, a sì fi agbára fún ẹni tí ó jókòó lórí rẹ̀, láti gba àlàáfíà kúrò lórí ilẹ̀ ayé, àti pé kí wọn kí ó máa pa ara wọn, a sì fi idà ńlá kan lé e lọ́wọ́.
4 Naatu horse tabo biyan woun anababatun tafanamaim orot baibiyow kaiy hitin auman titit aitin. Nati orot i tafaram wanawanan tufuw bosairin wouyinin isan ana baibasit hitin, saise sabuw hitiyaso’aso’ar taiyuwih hitayuwih hitatarih hitimumurub isan.
5 Nígbà tí ó sì di èdìdì kẹta, mo gbọ́ ohùn ẹ̀dá alààyè kẹta wí pé, “Wá wò ó”. Mo sì wò ó, sì kíyèsi i, ẹṣin dúdú kan; ẹni tí ó jókòó lórí rẹ̀ ní ìwọ̀n aláwẹ́ méjì ní ọwọ́ rẹ̀.
5 Buk baitounin hikwah inu’in Lamb bai kwibikwib ana veya, ayu sawar yawasih ma’anih baitounin fanan anowar eo, “Kuna!” Ayu anuwanuw horse biyan fufum tafanamaim orot uman siker rou’ab hitin bobotanen aitin.
6 Mo sì gbọ́ bí ẹni pé ohùn kan ní àárín àwọn ẹ̀dá alààyè mẹ́rẹ̀ẹ̀rin nì ti ń wí pé, òsùwọ̀n alikama kan fún owó idẹ kan, àti òsùwọ̀n ọkà barle mẹ́ta fún owó idẹ kan, sì kíyèsi i, kí ó má sì ṣe pa òróró àti ọtí wáìnì lára.
6 Naatu ayu nidun ta anonowar ana nowarin i sawar yawasih wanawanahimaim ta fananabe anowar eo, “Rafiy sum kikimin ana baiyan i veya ta’imon baiyan ana fofonin, naatu rafiy sum gidigidih tounu hai baiyan i veya ta’imon baiyan ana fofonin. Baise raiy naatu wine men kwani’afiyen!”
7 Nígbà tí ó sì ṣí èdìdì kẹrin, mo gbọ́ ohùn ẹ̀dá alààyè kan wí pé, “Wá wò ó!”
7 Buk baikwafi’inin hikwah inu’in Lamb bai kwibikwib ana veya, ayu sawar yawasih ma’anih baikwafi’inin fanan anowar eo, “Kuna!”
8 Mo sì wò ó, kíyèsi, ẹṣin ràndànràndàn kan, orúkọ ẹni tí ó jókòó lórí rẹ̀ ni ikú, àti ipò òkú sì tọ̀ ọ́ lẹ́yìn. A sì fi agbára fún wọn lórí ìdámẹ́rin ayé, láti fi idà, àti ebi, àti ikú, àti ẹranko lu orí ilẹ̀ ayé pa.
8 Ayu anuwanuw horse biyan wair tafanamaim orot wabin Morob ma’am aitin, naatu orot ta wabin Morobana’efan ufunika i’ufunun hairi hinanan aitin. Iti orot rou’ab i tafaram wanawanan auwaraunane turin ana fofonin sabuw kaiyomaim tar morob isan, baimar botaitin isan, sawow yumatah ta ta, sigarafor yubih morob isan ana fair hitih.
9 Nígbà tí ó sì ṣí èdìdì karùn-ún, mo rí lábẹ́ pẹpẹ, ọkàn àwọn tí a ti pa nítorí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, àti nítorí ẹ̀rí tí wọ́n dìímú,
9 Buk bai five hikwah inu’in Lamb kwibikwib ana veya, sabuw iyab God ana tur hibibinan isan, naatu hikukurereb isan hirouw himomorob, ayubih sibor ana gem babanamaim hima’am aitih.
10 Wọ́n kígbe ní ohùn rara, wí pé, “Yóò ti pẹ́ tó, Olúwa Olódùmarè, ẹni mímọ́ àti olóòtítọ́ ìwọ kì yóò ṣe ìdájọ́ kí o sì gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ wa mọ́ lára àwọn tí ń gbé orí ilẹ̀ ayé?”
10 Naatu iti sabuw fanah aumetawat hirerey hio, “Regah fair maiyow kakafiyi naatu turobe anababatun! Regah mar boro biy tafaram ana sabuw iyab aki hi’asbuni amomorob isan inibatiyih, aisa inabow baimakiy initih?”
11 A sì fi aṣọ funfun fún gbogbo wọn; a sì wí fún wọn pé, kí wọn kí ó sinmi fún ìgbà díẹ̀ ná, títí iye àwọn ìránṣẹ́ ẹlẹgbẹ́ wọn àti arákùnrin wọn tí a o pa bí wọn, yóò fi dé.
11 Etei’imak faifuw kwes ta’ita’imon hifaramih hi’osen naatu hi’uwih, mar kafai kwanakaif, kwa hi’asbuni kwamomorob na’atube akir wairafih, taituwa, hinarouw hinamorob nan ana fofonin nab.
12 Nígbà tí ó sì ṣí èdìdì kẹfà mo sì rí i, sì kíyèsi i, ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá kan ṣẹ̀; oòrùn sì dúdú bí aṣọ ọ̀fọ̀ onírun, òṣùpá sì dàbí ẹ̀jẹ̀;
12 Buk bai six hikwah inu’in Lamb bai kwibikwib ana veya, iriyoy gagamin na’in tit, veya matan fufum matar, watur tibifufum na’atube, sumar matan tutufin etei iwuwun rara matar,
13 àwọn ìràwọ̀ ojú ọ̀run sì ṣubú sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí igi ọ̀pọ̀tọ́ tí ń rẹ̀ àìgbó èso rẹ̀ dànù, nígbà tí ẹ̀fúùfù ńlá bá mì í.
13 maramaim daman hihururuwih me yan hire, fafou ro’oh ahiy wowog ebabin tibihururuwih na’atube.
14 A sì ká ọ̀run kúrò bí ìwé tí a ká, àti olúkúlùkù òkè àti erékùṣù ní a sì ṣí kúrò ní ipò wọn.
14 Fef tafifirorow na’atube mar taiyuwin firorow menika in, oyaw etei naatu nuw etei hai efanamaim sa’asa’abin hin.
15 Àwọn ọba ayé àti àwọn ọlọ́lá àti àwọn olórí ogun, àti àwọn ọlọ́rọ̀ àti àwọn alágbára, àti olúkúlùkù ẹrú, àti olúkúlùkù òmìnira, sì fi ara wọn pamọ́ nínú ihò ilẹ̀, àti nínú àpáta orí òkè;
15 Imaibo tafaram ana aiwob, orot wabih gagamih, baiyow hai ukwarih, sabuw sawar wairafih, sabuw fairih, akirwairafih, sabuw iyab men akir wairafih, etei hinunuw oyaw an watu wanawanah hirun, naatu kabay wa’aroh hirun hiwa’ir.
16 wọ́n sì ń wí fún àwọn òkè àti àwọn àpáta náà pé, “Ẹ wó lù wá, kí ẹ sì fi wá pamọ́ kúrò lójú ẹni tí ó jókòó lórí ìtẹ́, àti kúrò nínú ìbínú Ọ̀dọ́-Àgùntàn náà.
16 Imaibo hi’af ra’at oyaw naatu kabay toto hi’uwih re tounihimih hio, “Men akokok orot urama’ama afe’en ema’am matanamaim anama naatu Lamb ana yaso’ar wanawanan anarun.
17 Nítorí ọjọ́ ńlá ìbínú wọn dé; ta ni ó sì le dúró?”
17 Anayabin hai yaso’ar gagamin ana veya i natitaka, naatu yait boro iti yaso’ar nanafut?”
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Apocalipse 6, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.