Apocalipse 22
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Ó sì fi odò omi ìyè kan hàn mi, tí ó mọ́ bí kirisitali, tí ń tí ibi ìtẹ́ Ọlọ́run àti tí Ọ̀dọ́-Àgùntàn jáde wá,
1 Imaibo retab yan yawas ana harew matan kiriyamiyamin crystal na’atube God ana urama’ama naatu Lamb ana urama’ama’ane nunuw re’er i’obaiyu aitin.
2 ní àárín ìgboro rẹ̀, àti níhà èkínní kejì odò náà, ni igi ìyè gbé wà, tí o máa ń so onírúurú èso méjìlá, a sì máa so èso rẹ̀ ni oṣooṣù ewé igi náà sí wà fún mímú àwọn orílẹ̀-èdè láradà.
2 Iti harew i bar merar gagamin ana ef na’in yan foun in nununuw. Naatu harew rewan roun roun i yawas ana ai hibatabat aitah, iti ai i kwamur ta’imon wanawanan mar etei twelve ebiw, sumar matan eyiy, naatu ai rourin i tafaram ana yawas.
3 Ègún kì yóò sì ṣí mọ: ìtẹ́ Ọlọ́run àti tí Ọ̀dọ́-àgùntàn ni yóò sì máa wà níbẹ̀; àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò sì máa sìn ín.
3 Nati bar merar gagamin wanawanan God ana orarafen ta boro men inatita’ur. God ana urama’ama naatu Lamb ana urama’ama boro nati bar merar gagaminamaim hinama ana akir wairafih i hinakwafirih.
4 Wọ́n ó si máa rí ojú rẹ̀; orúkọ rẹ̀ yóò si máa wà ni iwájú orí wọn.
4 Yumatan boro hina’itin naatu wabin boro nakwetahimaim nakirum hinama.
5 Òru kì yóò sí mọ́; wọn kò sì ní wa ìmọ́lẹ̀ fìtílà, tàbí ìmọ́lẹ̀ oòrùn; nítorí pé Olúwa Ọlọ́run ni yóò tan ìmọ́lẹ̀ fún wọn: wọn ó sì máa jẹ ọba láé àti láéláé.
5 Nati’imaim gugumin boro en. Ramef ana marakaw naatu veya ana marakaw boro en, anayabin Regah God boro marakaw nitih, naatu i boro bairi hini’aiwob wanatowan, wanatowan.
6 Ó sì wí fún mi pé, “Òdodo àti òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ wọ̀nyí: Olúwa Ọlọ́run ẹ̀mí àwọn wòlíì ni ó sì ran angẹli rẹ̀ láti fi ohun tí ó ní láti ṣẹlẹ̀ láìpẹ́ yìí hàn àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀.”
6 Imaibo tounamatar iuwu, “Iti tur i anababatun turobe initumatum. Regah God sawar abisa boro hinamamatar isan i Anunin ana dinab orot hai tur eowen, naatu ana tounamatar iyafarih abisa boro’omo hinamamatar isan ana akir wairafih i’obaiyih.”
7 “Kíyèsi i, èmi ń bọ̀ kánkán! Ìbùkún ni fún ẹni tí ń pa ọ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ inú ìwé yìí mọ́!”
7 Kwananowar, ayu i boro’omo anan, dinabatur iti buk wanawanan hikikirum o yait inabifanabow boro baigegewasin inab.
8 Èmi, Johanu, ni ẹni tí ó gbọ́ tí ó sì ri nǹkan wọ̀nyí. Nígbà tí mo sì gbọ́ tí mo sì rí, mo wólẹ̀ láti foríbalẹ̀ níwájú ẹsẹ̀ angẹli náà, tí o fi nǹkan wọ̀nyí hàn mi.
8 Ayu John taiyuwu iti sawar fanah anowar naatu aitah naatu iti sawar fanah anowar ai’itah ana maramaim anamaim ara’iy tounamatar iti sawar bi’obaiyu akwafir.
9 Nígbà náà ni ó wí fún mi pé, “Wó ò, má ṣe bẹ́ẹ̀, ìránṣẹ́ ẹlẹgbẹ́ rẹ ni èmi, àti ti àwọn arákùnrin rẹ̀ wòlíì, àti ti àwọn tí ń pa ọ̀rọ̀ inú ìwé yìí mọ́. Foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run!”
9 Baise iuwu, “Men iti na’atube inasinaf, o ayu airit i God ana akir wairafit, taituwa baitumatumayah dinab oro’orot iyab iti buk wanawanan tibifanabow bairit. God akisin inakwafir.”
10 Ó sì wí fún mi pé, “Má ṣe fi èdìdì di ọ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ tí inú ìwé yìí, nítorí ìgbà kù sí dẹ̀dẹ̀.
10 Imaibo iuwu, “Dinabatur buk wanawanan hikirum inu’in men inarufut inikwah anayabin veya i nakabom.
11 Ẹni tí ń ṣe aláìṣòótọ́, kí ó máa ṣe aláìṣòótọ́ nì só; àti ẹni tí ń ṣe ẹlẹ́gbin, kí ó máa ṣe ẹ̀gbin nì só; àti ẹni tí ń ṣe olódodo, kí ó máa ṣe òdodo nì só; àti ẹni tí ń ṣe mímọ́, kí ó máa ṣe mímọ́ nì só.”
11 Yait ma kakafih esisinaf kwaihamiy ema kakafih esinaf. Yait ma yawas ebigugumas kwaihamiy ema igugumas. Yait ma mutufor esisinaf kwaihamiy ema mutufor esinaf. Yait taiyuwin ya’asair kakafiyinamaim ema’am kwaihamiy kakafiyinamaim ema.”
12 “Kíyèsi i, èmi ń bọ̀ kánkán; èrè mí sì ń bẹ pẹ̀lú mi, láti sán fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀ yóò tí rí.
12 “Kwananowar! ayu i boro’omo anan, umau’umaim i au baiyan abai auman naatu kwa ta’ita’imon abisa kwasisinafumaim boro anit.
13 Èmi ni Alfa àti Omega, ẹni ìṣáájú àti ẹni ìkẹyìn, ìpilẹ̀ṣẹ̀ àti òpin.
13 Ayu i Alpha naatu Omega, ayu i An naatu Yomanin, Busurufin naatu Baisawarin.
14 “Ìbùkún ni fún àwọn ti ń fọ aṣọ wọn, kí wọ́n lè ni ẹ̀tọ́ láti wá sí ibi igi ìyè náà, àti kí wọ́n lè gbà àwọn ẹnu ibodè wọ inú ìlú náà.
14 “Iyab hai faifuw hisouwen hibigewasin i hai baibasit ema’am boro yawas ana ai ro’on hina’aan baigegewasin hinab, naatu hai ef mutufor inu’in bar merar gagamin ana etawan hinarun.
15 Nítorí ni òde ni àwọn ajá gbé wà, àti àwọn oṣó, àti àwọn àgbèrè, àti àwọn apànìyàn, àti àwọn abọ̀rìṣà, àti olúkúlùkù ẹni tí ó fẹ́ràn èké tí ó sì ń hùwà èké.
15 Bar merar gagamin ufunane i sabuw kakafih haru’ube tema’am. Nati sabuw i farumayah, baiwa’an kwanekwaneyah, asbunubunuwayah, God ana baimataren sawar kwafirenayah, naatu sabuw iyab hai tur hai bowabowamaim tibifufuwen i tema’am.
16 “Èmi, Jesu, ni ó rán angẹli mi láti jẹ́rìí nǹkan wọ̀nyí fún yin ní tí àwọn ìjọ. Èmi ni gbòǹgbò àti irú-ọmọ Dafidi, àti ìràwọ̀ òwúrọ̀ tí ń tàn.”
16 “Ayu Jesu iti sawar kwa ekaleisia isa orereb isan au tounamatar ai yafar na. Ayu i David uwan naatu ana rara, naatu mar auman ana Maragias ana marakaw.”
17 Ẹ̀mí àti ìyàwó wí pé, “Máa bọ!” Àti ẹni tí ó ń gbọ́ kí ó wí pé, “Máa bọ̀!” Àti ẹni tí òǹgbẹ ń gbẹ kí ó wá, àti ẹni tí o bá sì fẹ́, kí ó gba omi ìyè náà lọ́fẹ̀ẹ́.
17 Anun Kakafiyin naatu tabin ana babitai hio, “Kuna!” Naatu iyab tur tenonowar i auman hinao, “Kuna! Naatu yait sikan emamamah kwaihamiyih tena, naatu yait nakokok yawas ana harew tomamih kwaihamiy ena ana siwaramih ebai etom.”
18 Èmi kìlọ̀ fún olúkúlùkù ẹni tó ń gbọ́ ọ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ inú ìwé yìí pé, bí ẹnikẹ́ni ba fi kún wọn, Ọlọ́run yóò fi kún àwọn ìyọnu tí a kọ sínú ìwé yìí fún un.
18 Ayu John kwa sabuw etei dinabatur iti buk wanawanan kwanonowar i abimatnuwi. Orot yait iti tur tafan nayaya’abar na’at, sawow kakafih yumatah ta ta iti buk wanawanan hio, God boro ibo tafan naya’abar baimakiy nitin.
19 Bí ẹnikẹ́ni bá sì mú kúrò nínú ọ̀rọ̀ ìwé ìsọtẹ́lẹ̀ yìí, Ọlọ́run yóò sì mú ipa tirẹ̀ kúrò nínú ìwé ìyè, àti kúrò nínú ìlú mímọ́ náà, àti kúrò nínú àwọn ohun tí a kọ sínú ìwé yìí.
19 Naatu orot yait dinabatur iti buk wanawanan hikikirum ta nabobosa’ir na’at, i aunowan yawas ana ai ro’on naatu bar merar gagamin isan hio, God boro nabosair.
20 Ẹni tí ó jẹ́rìí nǹkan wọ̀nyí wí pé, “Nítòótọ́ èmi ń bọ̀ kánkán.”
20 Orot iti sawar eo’orereb, eo, “Isa’amih, ayu boro’omo anan.”
21 Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Olúwa kí ó wà pẹ̀lú gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́. Àmín.
21 Manaw kabeber ata Regah Jesu’une kwa God ana sabuw etei isa nama. Amen.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Apocalipse 22, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.