Apocalipse 17
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Ọ̀kan nínú àwọn angẹli méje náà tí ó ní ìgò méje wọ̀n-ọn-nì sì wá, ó sì ba mi sọ̀rọ̀ wí pé, “Wá níhìn-ín; èmi ó sì fi ìdájọ́ àgbèrè ńlá ní tí ó jókòó lórí omi púpọ̀ han ọ,
1 Tounamatar sevenwanawanahimaim tounamatar ta tew bai seven bobotanen na eo, “Kuna ayu boro babin baiwa’an kwanekwaneyan wabin gagamin harew moumurih yan emamare’ere ana baimakiy ani’obaiy ina’itin.
2 ẹni tí àwọn ọba ayé bá ṣe àgbèrè, tí a sì fi ọtí wáìnì àgbèrè rẹ̀ pa àwọn tí ń gbé inú ayé.”
2 Tafaram ana aiwob hina bairi hiwa’an kwanekwan naatu tafaram ana sabuw baiwa’an kwanekwan ana wine hitom hikoko’aw.”
3 Ó sì gbé mi nínú ẹ̀mí lọ sí aginjù: mo sì rí obìnrin kan ó jókòó lórí ẹranko aláwọ̀ òdòdó kan tí ó kún fún orúkọ ọ̀rọ̀-òdì, ó ní orí méje àti ìwo mẹ́wàá.
3 Anun Kakafiyin targabuw tounamatar bora’ahu nawiyu ana arar yan atit. Nati’imaim sawaidab biyan woun ukwarin seven naatu ana rarag ten afe’enamaim babin ma’am aitin, naatu sawaidab biyan tutufin etei baigigimen tur God isan hikirumen hi’inu’in aitan.
4 A sì fi aṣọ elése àlùkò àti aṣọ òdòdó wọ obìnrin náà, a sì fi wúrà àti òkúta iyebíye àti perli ṣe é ní ọ̀ṣọ́, ó ní ago wúrà kan ní ọwọ́ rẹ̀, tí ó kún fún ìríra àti fún ẹ̀gbin àgbèrè rẹ̀;
4 Babin ana faifuw i namar naatu woun anababatun ius, naatu biyanamaim i gold, ton wakek, sar, kwameton rira’ara’ah, naatu umanamaim i ana sinaf kakafih yumatah ta ta kerowas gold amaim hiwan awan karatan,
5 àti níwájú rẹ̀ ni orúkọ kan tí a kọ:
5 nakwetanamaim i tur buriburin hikirum,
6 Mo sì rí obìnrin náà mu ẹ̀jẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́, àti ẹ̀jẹ̀ àwọn ajẹ́rìí ikú Jesu ní àmuyó.
6 Naatu babin God ana sabuw hai rara tom naatu sabuw Jesu ana tur hio’orereb hai rara tom bikoko’aw aitin, iti babin ai’itin ana veya’amaim ayu ai fofofor men kafaita.
7 Angẹli sì wí fún mi pé, “Nítorí kí ni ẹnu ṣe yà ọ́? Èmi ó sọ ti ìjìnlẹ̀ obìnrin náà fún ọ, àti ti ẹranko tí ó gùn, ti ó ní orí méje àti ìwo mẹ́wàá.
7 Imaibo tounamatar eo, “Aisim kubifofofor? Ayu boro nati babin ana buriburin, naatu nati sawaidab ukwarin seven naatu ana rarag ten babin afe’en ma ereremor ana buriburih ana kubuna inanowar.
8 Ẹranko tí ìwọ ri nì, o ti wà, kò sì ṣí mọ́, yóò sì ti inú ọ̀gbun gòkè wá, yóò sì lọ sínú ìparun rẹ. Àwọn olùgbé ayé ti a kọ orúkọ wọn sínú ìwé iye láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé, nígbà tí wọn ń wò ẹranko tí o ti wà, tí kò sì ṣí mọ́, tí ó sì ń bọ̀ wá, ẹnu si ya wọn.
8 Nati sawaidab i mat ma’am baise boun i men ema’am. Baise boro’omo murubih hai efan wanu’uminane nayen hinagurus. Sabuw tafaramamaim tema’am wabih tafaram matara’e ana veya, wanatowan ana bukamaim men hikikirum boro hinifofofor sawaidab hina’itin ana veya. Anayabin i marasika ma, boun i en baise boro nan.
9 “Níhìn-ín ni ìtumọ̀ tí o ní ọgbọ́n wà. Orí méje ni òkè ńlá méje ni, lórí èyí tí obìnrin náà jókòó.
9 “Ukwar narerekab naatu tur iti naniyan kwanab gewas. Sawaidab ukwarin seven i oyaw seven babin afe’en ema’am ana itinin.
10 Ọba méje sì ní wọn: àwọn márùn-ún ṣubú, ọ̀kan ń bẹ, ọ̀kan ìyókù kò sì tí ì dé; nígbà tí ó bá sì dé, yóò dúró fún ìgbà kúkúrú.
10 Naatu aiwob seven auman hai itinin. Five i himorob hire, ta’imon boun ebi’aiwob, naatu ta i boro enan, naatu i nanan ana veya i boro mar kafai ni’aiwob.
11 Ẹranko tí ó sì ti wà, tí kò sì ṣí, òun náà sì ni ẹ̀kẹjọ, ó sì ti inú àwọn méje náà wá, ó sì lọ sí ìparun.
11 Sawaidab marasika ma’am momorob i aiwob bai eight. Nati aiwob i iti aiwob seven ana kofan turin, naatu i auman enan gurugurusen wanawanan narunamih.
12 “Ìwo mẹ́wàá tí ìwọ sì rí ni ọba mẹ́wàá ni wọn, tí wọn kò ì ti gba ìjọba; ṣùgbọ́n wọn gba àṣẹ bí ọba pẹ̀lú ẹranko náà fún wákàtí kan.
12 Rarag etei ten i’itah i aiwob etei ten, tafaram bow bai aiwob isan ana fair i men ta hibai, baise mar kafai hour ta’imon ana fofonin boro aiwob rubabaruwin ana fair hinab sawaidab bairi hini’aiwob.
13 Àwọn wọ̀nyí ní inú kan, wọ́n yóò sì fi agbára àti ọlá wọn fún ẹranko náà.
13 Aiwob etei ten hai not i ta’imon naatu hai fair hai roubabaruwen etei boro sawaidab hinitin ni’aiwob.
14 Àwọn wọ̀nyí ni yóò si máa bá Ọ̀dọ́-Àgùntàn jagun, Ọ̀dọ́-Àgùntàn náà yóò sì ṣẹ́gun wọn: nítorí òun ni Olúwa àwọn Olúwa, àti ọba àwọn ọba: àwọn tí ó sì wà pẹ̀lú rẹ̀, tí a pè, tí a yàn, tí wọ́n sì jẹ́ olóòtítọ́ yóò sì ṣẹ́gun pẹ̀lú.”
14 Lamb bairi boro hinibabarfoten hiniyow, baise Lamb boro ana’afa’af sabuw, ana rourubinen sabuw naatu ana sabuw iyab hibosunusunub hibi’ufunun boro bairi hinabat hinarouw hinisbunih, anayabin i regaregah etei hai Regah, naatu aiwob etei hai Aiwob.”
15 Ó sì wí fún mi pé, “Àwọn omi tí ìwọ ti rí ni, níbi tí àgbèrè náà jókòó, àwọn ènìyàn àti ẹ̀yà àti orílẹ̀ àti onírúurú èdè ni wọ́n.
15 Imaibo Tounamatar iti na’atube iuwu, “Harew nati babin baiwa’an kwanekwaneyan tafah ma i’i’itin, i sabuw biyah ta ta, kou’ay ta ta, tafaram ta ta, naatu tur ta ta.
16 Àti ìwo mẹ́wàá tí ìwọ rí, àti ẹranko náà, àwọn wọ̀nyí ni yóò kórìíra àgbèrè náà, wọn ó sì sọ ọ́ di ahoro àti ẹni ìhòhò, wọn ó sì jẹ ẹran-ara rẹ̀, wọn ó sì fi iná sun ún pátápátá.
16 Sawaidab naatu rarag etei ten i’i’itih boro babin baiwa’an kwanekwaneyan hinifa’ifa’i, biyanamaim sawar etei boro hinabosaisiren segar hinihamiy nabat, biyan boro hina’aan naatu wairafamaim boro hina’afun biyan hinagurus.
17 Nítorí Ọlọ́run ti fi sínú ọkàn wọn láti mú ìfẹ́ rẹ̀ ṣẹ, láti ní inú kan, àti láti fi ìjọba wọn fún ẹranko náà, títí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run yóò fi ṣẹ.
17 Anayabin God iti sawar i dogorohimaim yari’iy ana kok abisa eo hinasinaf hinisawar, etei boro hinibasit sawaidab hai fair hinitin nabonawiyih nanan God ana tur nan niturobe.
18 Obìnrin tí ìwọ rí ní ìlú ńlá ni, tí ń jẹ ọba lórí àwọn ọba ilẹ̀ ayé.”
18 ‘Babin nati i’i’itin i bar merar gagamin, i tafaram wanawanan hai aiwob etei ebobonawiyih.”
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Apocalipse 17, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.