2 Samuel 24

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Ìbínú Olúwa sì ru sí Israẹli, ó sì ti Dafidi sí wọn, pé, “Lọ ka iye Israẹli àti Juda!”
1 E, mais uma vez, a ira do SENHOR acendeu-se contra Israel, e ele moveu Davi contra eles para dizer: Ide e enumerai Israel e Judá.
2 Ọba sì wí fún Joabu olórí ogun, tí ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ pé, “Lọ ní ìsinsin yìí sí gbogbo ẹ̀yà Israẹli láti Dani títí dé Beerṣeba, kí ẹ sì ka iye àwọn ènìyàn, kí èmi lè mọ iye àwọn ènìyàn náà!”
2 Porque o rei disse a Joabe, o capitão do exército, que estava com ele: Ide, agora, por todas as tribos de Israel, desde Dã até Berseba, e enumerai o povo, para que eu possa saber o número do povo.
3 Joabu sì wí fún ọba pé, “Kí Olúwa Ọlọ́run rẹ fi kún iye àwọn ènìyàn náà, iyekíye tí ó wù kí wọn jẹ́, ní ọ̀rọ̀ọ̀rún, ojú olúwa mi ọba yóò sì rí i, ṣùgbọ́n èétiṣe tí olúwa mi ọba fi fẹ́ nǹkan yìí?”
3 E Joabe disse ao rei: Ora, o SENHOR teu Deus acrescenta ao povo tantos quantos forem, um cêntuplo, e que os olhos do meu senhor, o rei, possam enxergar isto; mas, por que o meu senhor, o rei, deleita-se nesta coisa?
4 Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ ọba borí ti Joabu, àti ti àwọn olórí ogun. Joabu àti àwọn olórí ogun sì jáde lọ kúrò níwájú ọba, láti lọ ka àwọn ènìyàn Israẹli.
4 Não obstante, a palavra do rei prevaleceu contra Joabe, e contra os capitães do exército. E Joabe e os capitães do exército se retiraram da presença do rei para enumerar o povo de Israel.
5 Wọ́n sì kọjá odò Jordani, wọ́n sì pàgọ́ ní Aroeri, ní ìhà apá ọ̀tún ìlú tí ó wà láàrín àfonífojì Gadi, àti sí ìhà Jaseri.
5 E eles passaram sobre o Jordão, e acamparam em Aroer, no lado direito da cidade que se assenta no meio do rio de Gade, em direção a Jazer;
6 Wọ́n sì wá sí Gileadi, àti sí ilé Tatimi Hodṣi; wọ́n sì wá sí Dani Jaani àti yíkákiri sí Sidoni.
6 então eles chegaram a Gileade, e à terra de Cades; e chegaram a Dã-Jaã, e perto de Sidom,
7 Wọ́n sì wá sí ìlú olódi Tire, àti sí gbogbo ìlú àwọn Hifi, àti ti àwọn ará Kenaani, wọ́n sì jáde lọ síhà gúúsù ti Juda, àní sí Beerṣeba.
7 e chegaram à fortaleza de Tiro, e a todas as cidades dos heveus, e dos cananeus; e saíram em direção ao sul de Judá, até Berseba.
8 Wọ́n sì la gbogbo ilẹ̀ náà já, wọ́n sì wá sí Jerusalẹmu ní òpin oṣù kẹsànán àti ogúnjọ́.
8 Assim, quando haviam passado por toda a terra, chegaram a Jerusalém, ao fim de nove meses e vinte dias.
9 Joabu sì fi iye tí àwọn ènìyàn náà jásí lé ọba lọ́wọ́. Ó sì jẹ́ ogójì ọ̀kẹ́ (800,000) ọkùnrin alágbára ní Israẹli, àwọn onídà, àwọn ọkùnrin Juda sì jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n (500,000) ènìyàn.
9 E Joabe entregou a soma do número das pessoas ao rei; e havia em Israel oitocentos mil homens valentes que desembainhavam a espada; e os homens de Judá eram quinhentos mil homens.
10 Àyà Dafidi sì gbọgbẹ́ lẹ́yìn ìgbà tí ó ka àwọn ènìyàn náà tán. Dafidi sì wí fún Olúwa pé, “Èmi ṣẹ̀ gidigidi ní èyí tí èmi ṣe, ṣùgbọ́n, èmi bẹ̀ ọ, Olúwa, fi ẹ̀ṣẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ jì ní, nítorí pé èmi hùwà aṣiwèrè gidigidi!”
10 E o coração de Davi o feriu depois de ele haver enumerado o povo. E Davi disse ao SENHOR: Pequei grandemente naquilo que fiz; e, agora, suplico-te, ó SENHOR, retira a iniquidade do teu servo; porquanto agi mui loucamente.
11 Dafidi sì dìde ní òwúrọ̀, ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Gadi wòlíì wá, aríran Dafidi wí pé,
11 Porque, quando Davi estava de pé, pela manhã, a palavra do SENHOR veio ao profeta Gade, o vidente de Davi, dizendo:
12 “Lọ kí o sì wí fún Dafidi pé, ‘Báyìí ni Olúwa wí, èmi fi nǹkan mẹ́ta lọ̀ ọ́; yan ọ̀kan nínú wọn, kí èmi ó sì ṣe é sí ọ.’ ”
12 Vai e diz a Davi: Assim diz o SENHOR: Ofereço-te três coisas, escolhe uma delas para que eu possa fazê-la para ti.
13 Gadi sì tọ Dafidi wá, ó sì bi í léèrè pé, “Kí ìyàn ọdún méje ó tọ̀ ọ́ wá ní ilẹ̀ rẹ bí? Tàbí kí ìwọ máa sá ní oṣù mẹ́ta níwájú àwọn ọ̀tá rẹ, nígbà tí wọn ó máa lé ọ? Tàbí kí ààrùn ìparun ọjọ́ mẹ́ta ó wá sí ilẹ̀ rẹ? Rò ó nísinsin yìí, kí o sì mọ èsì tí èmi ó mú padà tọ ẹni tí ó rán mi.”
13 Assim, Gade veio até Davi, e contou-lhe, e lhe disse: Vir-te-ão sete anos de fome na tua terra? Ou queres tu fugir três meses diante dos teus inimigos, enquanto eles te perseguem? Ou que haja três dias de peste na tua terra? Agora, aconselha, e vê qual resposta devo retornar àquele que me enviou.
14 Dafidi sì wí fún Gadi pé, “Ìyọnu ńlá bá mi. Jẹ́ kí a fi ara wa lé Olúwa ní ọwọ́; nítorí pé àánú rẹ̀ pọ̀; kí ó má sì ṣe fi mí lé ènìyàn ní ọwọ́.”
14 E Davi disse a Gade: Estou em um grande aperto; que caiamos, agora, na mão do SENHOR; porque as suas misericórdias são grandes; e que eu não caia na mão de homem.
15 Olúwa sì rán ààrùn ìparun sí Israẹli láti òwúrọ̀ títí dé àkókò tí a dá, ẹgbẹ̀rún ní ọ̀nà àádọ́rin (70,000) ènìyàn sì kú nínú àwọn ènìyàn náà láti Dani títí fi dé Beerṣeba.
15 Assim, o SENHOR enviou uma peste sobre Israel desde a manhã até a hora determinada; e ali morreram do povo, desde Dã até Berseba, setenta mil homens.
16 Nígbà tí angẹli náà sì nawọ́ rẹ̀ sí Jerusalẹmu láti pa á run, Olúwa sì káàánú nítorí ibi náà, ó sì sọ fún angẹli tí ń pa àwọn ènìyàn náà run pé, “Ó tó, dá ọwọ́ rẹ dúró wàyí!” Angẹli Olúwa náà sì wà níbi ìpakà Arauna ará Jebusi.
16 E quando o anjo estendeu a sua mão sobre Jerusalém para destruí-la, o SENHOR se arrependeu do mal, e disse ao anjo que destruía o povo: Basta! Retém, agora, a tua mão. E o anjo do SENHOR estava junto à eira de Araúna, o jebuseu.
17 Dafidi sì wí fún Olúwa nígbà tí ó rí angẹli tí ń kọlu àwọn ènìyàn pé, “Wò ó, èmi ti ṣẹ̀, èmi sì ti hùwà búburú ṣùgbọ́n àwọn àgùntàn wọ̀nyí, kín ni wọ́n ha ṣe? Jẹ́ kí ọwọ́ rẹ, èmi bẹ̀ ọ́, kí ó wà lára mi àti ìdílé baba mi.”
17 E Davi falou ao SENHOR, quando viu o anjo que feria o povo, e disse: Eis que pequei e procedi impiamente; mas estas ovelhas, o que fizeram elas? Que a tua mão, rogo-te, esteja contra mim, e contra a casa do meu pai.
18 Gadi sì tọ Dafidi wá ní ọjọ́ náà, ó sì wí fún un pé, “Gòkè, tẹ́ pẹpẹ kan fún Olúwa lórí ilẹ̀ ìpakà Arauna ará Jebusi.”
18 E Gade veio naquele dia até Davi, e disse a ele: Sobe, levanta um altar ao SENHOR na eira de Araúna, o jebuseu.
19 Gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Gadi, Dafidi sì gòkè lọ bí Olúwa ti pa á ní àṣẹ.
19 E Davi, segundo o dizer de Gade, subiu, conforme ordenou o SENHOR.
20 Arauna sì wò, ó sì rí ọba àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ń bọ̀ wá lọ́dọ̀ rẹ̀, Arauna sì jáde, ó sì wólẹ̀ níwájú ọba ó sì dojú rẹ̀ bolẹ̀.
20 E Araúna olhou, e viu o rei e os seus servos vindo em sua direção; e Araúna saiu, e se curvou com o seu rosto em terra diante do rei.
21 Arauna sì wí pé, “Nítorí kín ni olúwa mi ọba ṣe tọ ìránṣẹ́ rẹ̀ wá?”
21 E Araúna disse: Por que veio o meu senhor, o rei, até o seu servo? E Davi disse: Para comprar de ti a eira, para construir um altar para o SENHOR, para que a praga possa ser detida do povo.
22 Arauna sì wí fún Dafidi pé, “Jẹ́ kí olúwa mi ọba ó mú èyí tí ó dára lójú rẹ̀, kí o sì fi í rú ẹbọ, wò ó, màlúù nìyìí láti fi ṣe ẹbọ sísun, àti ohun èlò ìpakà, àti ohun èlò mìíràn ti màlúù fún igi.
22 E Araúna disse a Davi: Que o meu senhor, o rei, tome e ofereça o que parecer bom a si; eis que aqui estão bois para sacrifício queimado, e instrumentos para joeiramento e outros instrumentos dos bois para lenha.
23 Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni Arauna fi fún ọba, bí ọba.” Arauna sì wí fún ọba pé, “Kí Olúwa Ọlọ́run rẹ ó gba ọrẹ rẹ.”
23 Todas estas coisas fez Araúna, como um rei dá ao rei. E Araúna disse ao rei: O SENHOR teu Deus te aceita.
24 Ọba sì wí fún Arauna pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́; ṣùgbọ́n èmi ó rà á ní iye kan lọ́wọ́ rẹ, bí ó ti wù kí ó ṣe; bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò fi èyí tí èmi kò náwó fún, rú ẹbọ sísun sí Olúwa Ọlọ́run mi.”
24 E o rei disse a Araúna: Não! Certamente desejo comprá-la de ti mediante um preço; tampouco oferecerei ofertas queimadas ao SENHOR meu Deus daquilo que não me custar nada. Assim, Davi comprou a eira e os bois por cinquenta shekels de prata.
25 Dafidi sì tẹ́ pẹpẹ kan níbẹ̀ sí Olúwa, ó sì rú ẹbọ sísun àti ti ìlàjà. Olúwa sì gbọ́ ẹ̀bẹ̀ fún ilẹ̀ náà, ààrùn náà sì dá kúrò ní Israẹli.
25 E Davi construiu ali um altar para o SENHOR, e ofereceu ofertas queimadas e ofertas de paz. Assim, o SENHOR foi suplicado em favor da terra, e a praga foi detida de Israel.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Samuel 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.